Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 26

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Tire

1 26.1–28.19: Isa 23; Jl 3.4-8; Am 1.9-10; Sk 9.3-4. ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kọ́kànlá, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, nítorí Tire sọ nípa Jerusalẹmu , Háà! A fọ́ èyí í ṣe bodè àwọn orílẹ̀-èdè, a i padà mi, èmi yóò di kíkún, òun yóò di ahoro,3 nítorí náà, báyìí Olúwa Olódùmarè , kíyèsi i, èmí dojúkọ ́ ìwọ tire, Èmi yóò jẹ́ Orílẹ̀-èdè púpọ̀ dìde , gẹ́gẹ́ Òkun ru sókè. 4 Wọn yóò odi tire lulẹ̀, wọn yóò wo ilé ìṣọ́ rẹ̀ lulẹ̀, Èmi yóò ha erùpẹ̀ rẹ̀ kúrò, Èmi yóò sọ ́ di orí àpáta. 5 Yóò jẹ́ ibi nína àwọ̀n wọn fi ń pẹja láàrín Òkun, Olúwa Olódùmarè . Yóò di ìkógun fún àwọn orílẹ̀-èdè. 6 Ìlú ó tẹ̀, àárín gbùngbùn ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó fi idà sọ ́ di ahoro. Nígbà náà wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.

7 "Nítorí báyìí Olúwa Olódùmarè : Kíyèsi i, láti ìhà àríwá ni èmi yóò ti Nebukadnessari ọba Babeli, ọba àwọn ọba, dìde Tire pẹ̀ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀àwọn ẹlẹ́ṣin àti ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ológun. 8 Yóò fi idà àwọn ọmọbìnrin rẹ oko, yóò kọ́ odi ́, yóò mọ òkìtì ́, yóò gbé àpáta sókè . 9 Yóò gbé ̀rọ ogun odi rẹ, yóò fi ohun èlò ogun ilé ìṣọ́ rẹ palẹ̀. 10 Àwọn ẹṣin rẹ̀ yóò pọ̀ wọn yóò fi eruku ́ mọ́lẹ̀. Àwọn ògiri rẹ yóò tìtì fún igbe àwọn ẹṣin ogun kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kẹ̀kẹ́ ogun nígbà ó wọ ẹnu-ọ̀odi gẹ́gẹ́ ènìyàn ń wọ ìlú láti inú àwọn ògiri rẹ̀ ti ó di fífọ́ pátápátá. 11 Pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin rẹ̀ ni yóò fi tẹ gbogbo òpópónà rẹ mọ́lẹ̀; yóò fi idà pa àwọn ènìyàn rẹ, àwọn ̀wọ́n rẹ ti o lágbára yóò palẹ̀. 12 Wọn yóò ọrọ̀ rẹ, wọn yóò fi òwò rẹ ṣe ìjẹ ogun; wọn yóò odi rẹ lulẹ̀, wọn yóò ba àwọn ilé rẹ dídára jẹ́, wọn yóò àwọn òkúta rẹ̀, àti igi ìtì ìkọ́rẹ̀, àti erùpẹ̀ rẹ̀, inú Òkun. 13 26.13: If 18.22.Èmi yóò ariwo orin rẹ̀ dákẹ́ àti ìró dùùrù orin rẹ̀ ni a yóò gbọ́ mọ́. 14 Èmi yóò sọ di àpáta lásán, ìwọ yóò di ibi a ń àwọ̀n ẹja . A yóò tún mọ nítorí Èmi Olúwa ti sọ ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè .

15 "Báyìí ni Olúwa Olódùmarè Tire: Ǹjẹ́ àwọn erékùṣù yóò ha wárìrì nípa ìṣubú rẹ, nígbà ìkórìíra ìpalára àti rírẹ́ni lọ́run ń ṣẹlẹ̀ inú rẹ? 16 26.16-17: If 18.9-10.Nígbà náà ni gbogbo àwọn ọmọ-aládé etí Òkun yóò sọ̀kalẹ̀ láti orí ìtẹ́ wọn, wọn yóò pa àwọn aṣọ ìgúnwà wọn da, wọn yóò bọ́ àwọn aṣọ iṣẹ́ ọnà abẹ́rẹ́ kúrò. ̀yóò wọ́n, wọn yóò jókòó lórí ilẹ̀ pẹ̀pẹ̀, wọn yóò máa wárìrì gbogbo ìgbà, ẹnu yóò wọ́n ́. 17 Nígbà náà wọn yóò gbóhùn ẹkún sókè nítorí rẹ, wọn yóò fún :

" Báwo ni a ṣe pa ́ run, ìwọ ìlú olókìkí

ìwọ àwọn èrò okun ti gbé inú rẹ̀!

Ìwọ jẹ alágbára lórí okun gbogbo

òun àti àwọn olùgbé inú rẹ̀;

ìwọ gbé ̀rẹ

lórí gbogbo olùgbé ibẹ̀.

18 Nísinsin yìí erékùṣù wárìrì

ọjọ́ ìṣubú rẹ;

erékùṣù ó nínú Òkun

ni ̀torí ìṣubú rẹ.

19 "Èyí yìí Olúwa Olódùmarè : Nígbà mo sọ ́ di ìlú ahoro, gẹ́gẹ́ bi àwọn ìlú a gbé inú wọn mọ́, àti nígbà èmi yóò ibú agbami Òkun orí rẹ, omi ńlá yóò ́, 20 nígbà èmi yóò wálẹ̀ pẹ̀àwọn ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, pẹ̀àwọn ènìyàn àtijọ́. Èmi yóò gbé lọ si bi ìsàlẹ̀, ibi ahoro àtijọ́, pẹ̀àwọn ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ihò, ìwọ yóò padà gbé inú rẹ̀ mọ́, èmi yóò gbé ògo kalẹ̀ ilẹ̀ àwọn alààyè. 21 Èmi yóò ṣe ̀, ìwọ yóò ṣí mọ́. a tilẹ̀ , síbẹ̀ a yóò tún mọ́, Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também