Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 46

1 " Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè , ẹnu-ọ̀àgbàlá ti inú ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn ni a pa fún ọjọ́ mẹ́a fi ń ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ọjọ́ ìsinmi àti ọjọ́ oṣù tuntun ni a ṣí i. 2 Ọmọ-aládé ni ó wọlé láti ìta ó kángun àbáwọlé ẹnu-ọ̀, ó dúró ẹnu-ọ̀. Àwọn àlùfáà ni yóò ọrẹ ẹbọ sísun rẹ̀ àti ọrẹ ìdàpọ̀. Òun ni yóò jọ́sìn ìloro ilé ẹnu-ọ̀, lẹ́yìn náà ni wọn yóò jáde, ṣùgbọ́n wọn ni ti ìlẹ̀kùn títí ìrọ̀lẹ́. 3 àwọn ọjọ́ ìsinmi àti àwọn oṣù tuntun ni àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà jọ́sìn iwájú Olúwa àbáwọlé ẹnu-ọ̀. 4 Ọrẹ ẹbọ sísun ọmọ-aládé fún Olúwa ni ọjọ́ ìsinmi láti jẹ́ ̀dọ́ àgbò mẹ́àti àgbò kan, gbogbo rẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́ aláìlábùkù. 5 Ọrẹ ẹbọ jíjẹ a papọ̀ mọ́ àgbò gbọdọ̀ jẹ́ efa kan, ọrẹ ẹbọ jíjẹ a pẹ̀àwọn ̀dọ́-àgùntàn ni ó gẹ́gẹ́ ó ṣe fẹ́, papọ̀ mọ hínì òróró kan pẹ̀efa kọ̀̀kan. 6 Àti ni ọjọ́ oṣù tuntun, ẹgbọrọ màlúù kan àìlábàwọ́n, àti ̀dọ́-àgùntàn mẹ́, àti àgbò kan: wọn o láìlábàwọ́n. 7 Yóò si pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ efa fun ẹgbọrọ akọ màlúù, àti efa kan fun àgbò kan, àti fun àwọn ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ bi èyí ti ipá rẹ̀ , àti hínì òróró kan fún efa kan. 8 Nígbà ọmọ-aládé wọlé, ó gbọdọ̀ gbá àbáwọlé ẹnu-ọ̀wọ inú, ó gba ibẹ̀ jáde.

9 " Nígbà àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà síwájú Olúwa ni àwọn àjọ̀dún a yàn, ẹnikẹ́ni ó gba ti ẹnu-ọ̀ìhà àríwá wọlé láti jọ́sìn gbọdọ̀ gba ti ẹnu-ọ̀ìhà gúúsù jáde; ẹnikẹ́ni ó gba ti ẹnu-ọ̀ìhà gúúsù wọlé yóò gba ẹnu-ọ̀ìhà àríwá jáde. ẹni ó gbọdọ̀ gba ibi ó wọlé jáde, ṣùgbọ́n olúkúlùkù gba òdìkejì ẹnu-ọ̀ó gbà wọlé jáde. 10 Ọmọ-aládé gbọdọ̀ àárín wọn, ó wọlé nígbà wọn wọlé, ó jáde nígbà wọn jáde.

11 " Níbi àwọn àjọ̀dún àti àwọn àjọ̀dún a yàn, ọrẹ ẹbọ jíjẹ gbọdọ̀ jẹ́ efa kan fún ẹgbọrọ akọ màlúù kan, efa kan fún àgbò kan, àti fún àwọn ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ ó ti wu onílúlùkù, pẹ̀òróró hínì kan fún efa kan. 12 Nígbà ọmọ-aládé pèsè ọrẹ àtinúwá fún Olúwa yálà ọrẹ ẹbọ sísun tàbí ọrẹ ẹbọ ìdàpọ̀ ojú ̀ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn ni ó ni ṣíṣí sílẹ̀ fún un. Òun yóò ọrẹ ẹbọ sísun rẹ̀ tàbí ọrẹ ẹbọ ìdàpọ̀ gẹ́gẹ́ òun ti ṣe ọjọ́ ìsinmi. Lẹ́yìn náà, òun yóò jáde, lẹ́yìn ìgbà ó jáde tán wọn yóò ti ẹnu-ọ̀.

13 " ojoojúmọ́ ni ìwọ yóò pèsè ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan aláìlábùkù fún ọrẹ ẹbọ sísun Olúwa; àràárọ̀ ni ìwọ yóò máa pèsè rẹ̀. 14 Ìwọ yóò máa pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ pẹ̀rẹ̀ àràárọ̀, èyí yóò ni ìdámẹ́nínú efa àti ìdámẹ́nínú òróró hínì láti fi po ìyẹ̀fun. Gbígbé ọrẹ ẹbọ jíjẹ fún Olúwa jẹ́ ìlànà ó títí. 15 Nítorí náà ̀dọ́-àgùntàn àti ọrẹ ẹbọ jíjẹ àti òróró ni wọn yóò pèsè àràárọ̀ fún ọrẹ ẹbọ sísun ìgbà gbogbo.

16 " Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè sọ, ọmọ-aládé ọrẹ láti inú ogún ìní rẹ̀ fún ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, yóò jẹ́ ìní tiwọn nípa ogún jíjẹ. 17 ó ọrẹ láti inú ogún ìní rẹ̀ fún ̀kan lára àwọn ọmọ ̀dọ̀, ọmọ le pamọ́ títí di ọdún ìdásílẹ̀, lẹ́yìn náà yóò padà ̀dọ̀ ọmọ-aládé. Ogún ìní rẹ̀ jẹ́ ti àwọn ọmọ rẹ̀ nìkan; ó jẹ́ tiwọn. 18 Ọmọ-aládé gbọdọ̀ nǹkan kan lára ogún ìní àwọn ènìyàn, tàbí wọn kúrò níbi ohun ìní wọn. Ó láti fi ogún ìní rẹ̀ láti inú ìní rẹ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀, a ma ba à ya nǹkan kan kúrò lára ìní rẹ̀.’ "

19 Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà mi kọjá àbáwọlé ó lẹ́bàá ẹnu-ọ̀, àwọn yàrá mímọ́ ó kọjú ìhà àríwá, èyí ó jẹ́ àwọn àlùfáà, ó fi ibi kan hàn apá ìwọ̀-oòrùn. 20 O sọ fún mi , "Èyí yìí ni ibi àwọn àlùfáà yóò ti ṣe ọrẹ ẹbọ ìdálẹ́bi àti ọrẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀, àti wọn yóò ti ṣe ọrẹ ẹbọ jíjẹ, láti ṣe jẹ́ wọn wọn ìta àgbàlá, wọn ya àwọn ènìyàn mímọ́."

21 Ó mi lọ ìta àgbàlá, ó mi igun mẹ́rẹ̀̀rin rẹ̀ , mo ri àgbàlá mìíràn igun kọ̀̀kan. 22 igun mẹ́rẹ̀̀rin ìta àgbàlá ó pẹnu pọ̀, ogójì ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn àti ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ìbú; àgbàlá kọ̀̀kan ni igun kọ̀̀kan jẹ́ ìwọ̀n kan náà. 23 agbègbè inú ̀kọ̀̀kan nínú àgbàlá náà ni ọwọ́ ilẹ̀ kan yíká wọn, a ṣe ibi ìdáná si abẹ́ ọwọ́ náà yípo. 24 Ó fún mi , "Ìwọ̀nyí ni àwọn ilé ìdáná níbi ó ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú tẹmpili yóò ti ṣe ẹbọ fún àwọn ènìyàn."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também