Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 19

Orin ọfọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli

1 "Kọ orin ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli 2 :

" Èwo nínú abo kìnnìún ni ìyá rẹ̀ àárín àwọn kìnnìún yòókù?

Ó sùn àárín àwọn ̀dọ́ kìnnìún ó ń tọ́àwọn ọmọ rẹ̀.

3 Ó tọ́ ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó di kìnnìún agbára,

ó kọ́ láti ṣọdẹ, ó ń pa àwọn ènìyàn jẹ.

4 Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀,

wọ́n fi ̀wọ̀n un nínú iho wọn.

Wọn fi ̀wọ̀n mu nu lọ ilẹ̀ Ejibiti.

5 " Nígbà abo kìnnìún yìí ìrètí rẹ̀ jásí asán,

ó ọmọ rẹ̀ mìíràn ó tún tọ́ dàgbà di kìnnìún agbára.

6 Ó ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí ó ti lágbára,

o kọ ọdẹ ṣíṣe, ó pa àwọn ènìyàn.

7 Ó odi wọn palẹ̀ ó sọ àwọn ìlú wọn di ahoro.

Ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé ibẹ̀ ìpayà nítorí bíbú ramúramù rẹ̀.

8 Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde i,

àwọn yìí láti ìgbèríko .

Wọn dẹ àwọ̀n wọn fún un,

wọn nínú ihò wọn.

9 Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn un lọ ̀dọ̀ ọba Babeli,

wọn fi sínú ìhámọ́, a gbọ́ bíbú rẹ̀ mọ́ lórí òkè Israẹli.

10 " Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀;

á gbìn etí odò ó, kún fún èso,

ó kún fún ̀ka nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ omi.

11 Àwọn ̀ka rẹ̀ lágbára láti fi ṣe ̀àṣẹ ìjòyè,

ó ga sókè láàrín ewé rẹ̀,

gíga rẹ̀ hàn jáde láàrín ̀pọ̀lọpọ̀ ̀ka rẹ̀.

12 Ṣùgbọ́n ó á tu ìrunú,

á wọ́ lulẹ̀,

afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn gbé èso rẹ̀,

̀líle rẹ̀ ti ṣẹ́, ó rọ

iná wọn run.

13 Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀

ni ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ ń pòǹgbẹ omi.

14 Iná jáde láti ̀kan lára ̀ka rẹ̀

ó pa ̀ka àti èso rẹ̀ run,

bi ̀ka lágbára lórí rẹ̀ mọ́;

èyí to ṣe fi ṣe ̀fún olórí mọ́.’

Èyí ni orin ̀fọ̀ a o máa lo orin ̀fọ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também