Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 15

Jerusalẹmu, àjàrà wúlò

1 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 2 "Ọmọ ènìyàn, báwo ni igi àjàrà ṣe dára ju igi mìíràn lọ tàbí ̀ka àjàrà láàrín igi yòókù nínú igbó? 3 Ǹjẹ́ a wa igi lára rẹ̀ ṣe nǹkan ó wúlò ? Tàbí ènìyàn fi ṣe èèkàn yóò fi nǹkan kọ́? 4 Lẹ́yìn èyí, ṣe a ú sínú iná gẹ́gẹ́ epo ìdáná, gbogbo igun rẹ̀ jóná pẹ̀àárín rẹ, ṣé o le wúlò fún nǹkan kan mọ́? 5 wúlò fún nǹkan kan nígbà lódidi, báwo ni yóò ṣe wúlò nígbà iná ti o, dúdú nítorí èéfín?

6 "Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè , mo ṣe sọ igi àjàrà láàrín àwọn igi inú igbó yòókù di igi ìdáná, bẹ́̀ ni Èmi yóò ṣe ṣe gbogbo ènìyàn ń gbé Jerusalẹmu. 7 Èmi yóò dojúkọ wọ́n. tilẹ̀ jẹ́ wọn ti jáde kúrò nínú iná kan, síbẹ̀ iná mìíràn yóò pàpà wọn. Nígbà mo dojúkọ wọ́n, ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa. 8 Èmi yóò sọ ilé náà di ahoro nítorí ìwà àìṣòótọ́ wọn, ni Olúwa Olódùmarè ."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também