Pular para o conteúdo
Publicidade

Esekiẹli 28

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì ọba Tire

1 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : 2 28.2: Da 11.36; 2Tẹ 2.4; If 13.5."Ọmọ ènìyàn, sọ fún ọmọ-aládé Tire , Báyìí Olúwa Olódùmarè :

" Nítorí ọkàn rẹ gbé sókè mi,

ìwọ , "Èmi ni Ọlọ́run;

Èmi jókòó orí ìtẹ́ òrìṣà,

àárín gbùngbùn Òkun."

Ṣùgbọ́n ènìyàn ni ́, i ṣe òrìṣà,

ó tilẹ̀ jẹ́ ìwọ ìwọ gbọ́n Ọlọ́run.

3 Ìwọ gbọ́n ju Daniẹli lọ ?

Ṣé àṣírí kan ó pamọ́ fún ?

4 Pẹ̀ọgbọ́n àti ìmọ̀ rẹ,

ìwọ jèrè ọrọ̀ fún ara rẹ,

àti àkójọpọ̀ wúrà àti fàdákà,

nínú àwọn ilé ìṣúra rẹ.

5 Nípa ọgbọ́n rẹ ńlá àti nípa òwò rẹ,

ìwọ ti sọ ọrọ̀ rẹ di púpọ̀,

àti nítorí ọrọ̀ rẹ di púpọ̀,

ọkàn rẹ gbé sókè,

nítorí ọrọ̀ rẹ.

6 " Nítorí náà èyí yìí Olúwa Olódùmarè :

" Nítorí ìwọ o gbọ́n,

ìwọ gbọ́n Ọlọ́run.

7 Èmi yóò àwọn àjèjì dìde ,

ẹlẹ́nínú àwọn orílẹ̀-èdè;

wọn yóò yọ idà wọn ,

ẹwà rẹ àti ọgbọ́n rẹ,

wọn yóò ba dídán rẹ̀ jẹ́.

8 Wọn yóò sọ̀kalẹ̀ sínú ihò,

ìwọ yóò ikú gbígbóná,

àwọn a pa àárín Òkun.

9 Ṣé ìwọ yóò , "Èmi ni Ọlọ́run,"

ojú àwọn ó pa ́?

Ìwọ yóò jẹ́ ènìyàn, í ṣe Ọlọ́run,

ọwọ́ àwọn ti yóò pa ́.

10 Ìwọ yóò ikú aláìkọlà,

ọwọ́ àwọn àjèjì.

Èmi ni ó ti sọ ́, Olúwa Olódùmarè .’ "

11 ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : 12 "Ọmọ ènìyàn, pohùnréré ẹkún sórí ọba Tire ó sọ fún un : Èyí yìí ni ohun Olúwa Olódùmarè :

" Ìwọ jẹ́ àpẹẹrẹ ìjẹ́pípé náà,

o kún fún ọgbọ́n,

o ẹwà.

13 Ìwọ ti Edeni, ọgbà Ọlọ́run;

onírúurú òkúta oníyebíye ni ìbora rẹ;

sardiu, topasi àti diamọndi, berili, óníkìsì,

àti jasperi, safire, emeradi,

turikuose, àti karbunkili, àti wúrà,

ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ àti àwọn òkè rẹ a ,

láti ara wúrà,

ọjọ́ á a pèsè wọn.

14 A fi àmì òróró yàn ́ gẹ́gẹ́ olùtọ́kérúbù,

torí èyí ni mo fi yàn ́.

Ìwọ lórí òkè mímọ́ Ọlọ́run;

ìwọ rìn ni àárín òkúta a iná.

15 Ìwọ ̀rẹ,

láti ọjọ́ a ti ,

títí a fi àìṣedéédéé inú rẹ.

16 Nípa ìtànkálẹ̀ òwò rẹ,

ìwọ kún fún ìwà ipá;

ìwọ dẹ́ṣẹ̀.

Nítorí náà ni mo ṣe sọ ,

ohun àìlọ́wọ̀ kúrò lórí òkè Ọlọ́run.

Èmi pa run,

ìwọ kérúbù, ó bọ́ kúrò àárín òkúta a iná.

17 Ọkàn rẹ gbéraga,

nítorí ẹwà rẹ.

Ìwọ ba ọgbọ́n rẹ jẹ́,

nítorí dídára rẹ.

Nítorí náà mo le sórí ayé;

mo sọ di awòojú níwájú àwọn ọba.

18 Nípa ̀ṣẹ̀ púpọ̀ rẹ àti òwò àìṣòótọ́ rẹ,

ìwọ ti ba àwọn ibi mímọ́ rẹ jẹ́.

Nítorí náà mo iná jáde ,

láti inú rẹ, yóò run,

èmi yóò sọ ́ di eérú lórí ilẹ̀,

lójú gbogbo àwọn ó ń ́.

19 Gbogbo orílẹ̀-èdè ó mọ̀ ́n,

ẹnu ń ;

ìwọ yóò jẹ́ ̀,

ìwọ yóò ṣí mọ́ láéláé.’ "

Àsọtẹ́lẹ̀ òdì Sidoni

20 28.20-26: Jl 3.4-8; Sk 9.2. ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ : 21 "Ọmọ ènìyàn, kọ ojú Sidoni; o sọtẹ́lẹ̀ i, 22 ó , Báyìí ni Olúwa Olódùmarè :

" Èmi lòdì , ìwọ Sidoni,

a ó ṣe lógo láàrín rẹ.

Wọn yóò mọ̀ èmi Olúwa,

nígbà mo ìdájọ́ mi ṣẹ nínú rẹ,

a mímọ́ nínú rẹ.

23 Èmi yóò rán àjàkálẹ̀-ààrùn sínú rẹ,

èmi yóò ̀jẹ̀ sàn ìgboro rẹ,

ẹni ti á pa yóò ṣubú àárín rẹ,

pẹ̀idà lára rẹ gbogbo ̀gbẹ́,

nígbà náà wọn yóò mọ̀ èmi ni Olúwa.

24 " yóò ṣí ̀gún ń gun ni ilẹ̀ Israẹli mọ́, tàbí ̀gún bíbani nínú jẹ́ ti gbogbo àwọn wọn àyíká wọn, wọ́n ń fi ojú yẹpẹrẹ wọ́n, nígbà náà ni wọn yóò mọ́ èmi ni Olúwa Olódùmarè.

25 " Èyí yìí Olúwa Olódùmarè : Nígbà èmi yóò sa àwọn ènìyàn Israẹli jọ kúrò gbogbo orílẹ̀-èdè wọ́n ti fọ́nká , a ó mímọ́ láàrín wọn lójú àwọn aláìkọlà. Nígbà náà ni wọn yóò gbé ilẹ̀ àwọn tìkálára wọn, èyí mo fún ìránṣẹ́ mi Jakọbu. 26 Wọn yóò máa gbé inú rẹ̀ àìléwu, wọn yóò kọ́, wọn yóò gbin ọgbà àjàrà; nítòótọ́ wọn yóò ìbàlẹ̀ àyà, nígbà èmi ti ìdájọ́ mi ṣẹ̀ ara àwọn ń ṣátá wọn gbogbo àyíká wọn. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também