Pular para o conteúdo
Publicidade

Numeri 27

Ọmọbìnrin Selofehadi

1 27.1-11: Nu 36.1-12. Ọmọbìnrin Selofehadi ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri ọmọ Manase jẹ́ ìdílé Manase, ọmọ Josẹfu . Orúkọ àwọn ọmọbìnrin náà ni Mahila, Noa, Hogla, Milka àti Tirsa. 2 Wọ́n súnmọ́ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé wọ́n dúró níwájú Mose, àti Eleasari àlùfáà, àti níwájú àwọn olórí àti ìjọ, wọ́n , 3 "Baba wa aginjù. lára àwọn ẹgbẹ́ Kora wọ́n ara wọn pọ̀ lòdì Olúwa, ṣùgbọ́n ó nítorí ̀ṣẹ̀ rẹ̀ fi ọmọkùnrin sílẹ̀. 4 Kín ni ó orúkọ baba wa yóò parẹ́ nínú ìdílé rẹ̀ nítorí ọmọkùnrin? Fún wa ilẹ̀ ìní láàrín àwọn arákùnrin baba wa."

5 Nígbà náà Mose ̀rọ̀ wọn síwájú Olúwa. 6 Olúwa fún un , 7 "Ohun àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ń sọ tọ̀. O gbọdọ̀ fún wọn ogún ìní ti baba wọn.

8 "Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ọkùnrin kan fi ọmọkùnrin sáyé, fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ ogún ìní rẹ̀. 9 ọmọbìnrin, fi ohun ìní rẹ́ fún àwọn arákùnrin rẹ̀. 10 arákùnrin, fi ogún ìní rẹ̀ fún arákùnrin baba rẹ̀. 11 baba rẹ̀ arákùnrin, fún ará ilé rẹ̀ ó súnmọ́ ìdílé rẹ̀ ogún ìní rẹ̀, ó jogún rẹ̀. Èyí gbọdọ̀ jẹ́ ìlànà ìdájọ́ fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.’ "

Joṣua láti rọ́Mose

12 27.12-14: De 3.23-27; 32.48-52. Nígbà náà Olúwa sọ fún Mose , "Lọ orí òkè Abarimu yìí, o lọ wo ilẹ̀ mo fún àwọn ọmọ Israẹli. 13 Lẹ́yìn ìgbà o ti i, ìwọ náà yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn rẹ gẹ́gẹ́ Aaroni arákùnrin rẹ ṣe ṣe, 14 nítorí nígbà ìlú ṣọ̀tẹ̀ níbi omi aginjù Sini, gbogbo yín ṣe àìgbọ́ràn mi láti mímọ́ níwájú wọn." (Èyí ni omi Meriba Kadeṣi aginjù Sini.)

15 Mose sọ fún Olúwa , 16 "Jẹ́ Olúwa, Ọlọ́run ̀gbogbo ènìyàn, ó yan ọkùnrin kan orí ìjọ ènìyàn yìí, 17 láti máa darí wọn, ẹni yóò wọn jáde, yóò wọn wọlé, gbogbo ènìyàn Olúwa yóò dàbí àgùntàn olùṣọ́."

18 27.18-23: De 3.28. Nígbà náà Olúwa sọ fún Mose , "Joṣua ọmọ Nuni, ọkùnrin nínú ẹni èmi , o gbé ọwọ́ rẹ e. 19 Jẹ́ ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti ojú gbogbo àwọn ìjọ ènìyàn Israẹli o fi àṣẹ fún un ojú wọn. 20 ìwọ ó fi nínú ọláńlá rẹ i lára, gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli ó gbọ́rọ̀ i lẹ́nu. 21 ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà, yóò gba ìpinnu fún láti béèrè Urimu níwájú Olúwa. Gẹ́gẹ́ òfin yìí ni òun pẹ̀gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli yóò jáde lọ, pẹ̀òfin rẹ̀ ni wọn ó wọlé."

22 Mose ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ fún un. Ó Joṣua ó ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti níwájú gbogbo ìjọ. 23 27.23: De 31.23.Nígbà náà ni ó gbé ọwọ́ rẹ̀ le e, ó fi àṣẹ fún un gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também