Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Kronika 11

Olúwa Kọ̀ fún Juda láti Israẹli Jagun

1 11.1-4: 1Ọb 12.22-24. Nígbà Rehoboamu Jerusalẹmu, ó ilé Juda àti Benjamini jọ, ̀kẹ́ mẹ́sàn-án (180,000) ènìyàn a yàn, wọ́n jẹ́ ológun, láti Israẹli ó ìjọba náà padà bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀.

2 Ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Olúwa tọ Ṣemaiah ènìyàn Ọlọ́run , 3 "fún Rehoboamu ọmọ Solomoni ọba Juda, gbogbo àwọn ọmọ Israẹli Juda àti Benjamini, 4 Èyí ohun Olúwa . ṣe gòkè lọ láti lọ pẹ̀arákùnrin yín, lọ sílé, gbogbo yín, nítorí ti ìṣe mi nìyí.’ " Bẹ́̀ ni wọ́n tẹ̀̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n padà sẹ́yìn láti yan lọ dojúkọ Jeroboamu.

5 Rehoboamu ń gbe Jerusalẹmu ó kọ́ àwọn ìlú fún olódi Juda. 6 Bẹtilẹhẹmu, Etamu, Tekoa, 7 Beti-Suri, Soko, Adullamu, 8 Gati, Meraṣa Sifi, 9 Adoraimu, Lakiṣi, Aseka 10 Sora, Aijaloni, àti Hebroni. Wọ̀nyí ni àwọn ìlú ìdáàbòbò Juda àti Benjamini. 11 Ó àwọn ìlú olódi lágbára, ó fi àwọn balógun sínú wọn àti àkójọ oúnjẹ, àti òróró àti ọtí wáìnì. 12 Àti olúkúlùkù ìlú ni ó fi asà àti ̀kọ̀ , ó wọn lágbára gidigidi, ó Juda àti Benjamini lábẹ́ rẹ̀.

Àwọn ọmọ Lefi dúró pẹ̀Juda

13 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi, láti gbogbo ̀wọn jákèjádò Israẹli ̀rẹ̀. 14 Àwọn ará Lefi fi ìgbèríko sílẹ̀, wọ́n Juda àti Jerusalẹmu nítorí Jeroboamu àti àwọn ọmọ rẹ̀, ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀ gẹ́gẹ́ àwọn àlùfáà Olúwa. 15 Ó yan àwọn àlùfáà tirẹ̀ fún àwọn ibi gíga wọ̀n-ọn-nì, àti fún àwọn ère òbúkọ, àti fún ẹgbọrọ màlúù ó ṣe. 16 Àwọn láti gbogbo ̀Israẹli wọ́n fi ọkàn wọn fún wíwá Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tẹ̀àwọn ará Lefi lọ Jerusalẹmu láti lọ ẹbọ Olúwa Ọlọ́run baba a wọn. 17 Ó fún ìjọba Juda agbára, ó ti Rehoboamu ọmọ Solomoni lẹ́yìn fún ọdún mẹ́ta nítorí ọdún mẹ́ta ni wọ́n fi rìn ̀ti Dafidi àti Solomoni àkókò .

Rehoboamu obìnrin jọ fún ara rẹ̀

18 Rehoboamu fẹ́ Mahalati ó jẹ́ ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Dafidi Jerimoti bi àti ti Abihaili, ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Jese Eliabu . 19 Ó àwọn ọmọ fún un: Jeuṣi, Ṣemariah àti Sahamu. 20 Nígbà náà, ó fẹ́ Maaka ọmọbìnrin Absalomu, ó Abijah fún Attai, Sisa àti Ṣelomiti. 21 Rehoboamu fẹ́ràn Maaka ọmọbìnrin Absalomu ju èyíkéyìí nínú àwọn ìyàwó rẹ̀ àti àwọn àlè rẹ̀ lọ. gbogbo rẹ̀, ó ìyàwó méjìdínlógún àti ọgọ́ta àlè ọmọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n àti ọgọ́ta ọmọbìnrin.

22 Rehoboamu yan Abijah ọmọ Maaka láti jẹ́ olóyè ọmọ-aládé láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, ó ba à ṣe é ọba. 23 Ó hùwà ọlọ́gbọ́n, nípa fọ́n díẹ̀ nínú àwọn ọmọ rẹ̀ jákèjádò àwọn agbègbè Juda àti Benjamini àti gbogbo àwọn ìlú ńlá olódi. Ó fún wọn ̀pọ̀ ohun wọ́n fẹ́, ó fẹ́ ̀pọ̀ ìyàwó fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também