Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 11

1 Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Jeremiah : 2 "Fetísílẹ̀ ̀rọ̀ májẹ̀yìí, o sọ wọ́n fún àwọn ènìyàn Juda, àti gbogbo àwọn ń gbé ni Jerusalẹmu. 3 Sọ fún wọn èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli : Ègbé ni fún ẹni náà pa ̀rọ̀ májẹ̀yìí mọ́. 4 Àwọn májẹ̀mo pàṣẹ fún àwọn baba ńlá yín, nígbà mo wọn jáde láti Ejibiti, láti inú iná alágbẹ̀dẹ .Mo , gbọ́ tèmi, ṣe ohun gbogbo mo pàṣẹ fún un yín. ̀yin ó jẹ́ ènìyàn mi, Èmi ó jẹ́ Ọlọ́run yín. 5 Nígbà náà ni Èmi ó ìlérí mo búra fún àwọn baba ńlá yín ṣẹ; láti fún wọn ilẹ̀ ó ń sàn fún wàrà àti fún oyin,ilẹ̀ lónìí."

Mo dáhùn , "Àmín, Olúwa."

6 Olúwa fún mi , "Kéde gbogbo ̀rọ̀ yìí àwọn ìlú Juda àti gbogbo òpópónà ìgboro Jerusalẹmu , gbọ́ ̀rọ̀ májẹ̀yìí, se wọn. 7 Láti ìgbà mo ti àwọn baba yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti títí di òní, mo kìlọ̀ fún wọn lọ́pọ̀ ìgbà , "gbọ́ tèmi." 8 Ṣùgbọ́n wọn gbọ́, bẹ́̀ ni wọn kọbi ara i dípò èyí wọ́n tẹ̀síwájú ni agídí ọkàn wọn. Mo gbogbo ègún inú májẹ̀mo ti ṣèlérí, mo ti pàṣẹ fún wọn láti tẹ̀, wọn tẹ̀wa sórí wọn.’ "

9 Olúwa fún mi , "̀tẹ̀ kan láàrín àwọn ará Juda àti àwọn ń gbé Jerusalẹmu. 10 Wọ́n ti padà ìdí ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wọn wọn kọ̀ láti tẹ́̀rọ̀ mi, wọ́n ti tẹ̀àwọn ọlọ́run mìíràn láti sìn wọ́n. Ilé Israẹli àti ilé Juda ti ba májẹ̀mo pẹ̀àwọn baba ńlá wọn jẹ́. 11 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa : Èmi yóò mu ibi wọn le è yẹ̀ sórí wọn, wọ́n tilẹ̀ èmi yóò fetí igbe wọn. 12 Àwọn ìlú Juda àti àwọn ará Jerusalẹmu yóò lọ kégbe àwọn òrìṣà wọ́n ń sun tùràrí ; àwọn òrìṣà náà ràn wọ́n lọ́wọ́ ìgbà ìpọ́njú náà . 13 Ìwọ Juda, iye àwọn ìlú rẹ, bẹ́̀ iye àwọn òrìṣà rẹ; bẹ́̀ ni iye pẹpẹ ̀yin ti tẹ́ fún sísun tùràrí Baali ohun ìtìjú n ṣe pọ̀ iye òpópónà ó Jerusalẹmu.

14 "ṣe gbàdúrà fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí tàbí o bẹ̀bẹ̀ fún wọn, nítorí , Èmi yóò dẹtí wọn nígbà wọ́n ìgbà ìpọ́njú.

15 "ni olùfẹ́ mi í ṣe tẹmpili mi,

òun àti àwọn mìíràn ṣe ń hu oríṣìíríṣìí ìwà àrékérekè?

Ǹjẹ́ ẹran a sọ́tọ̀ ìjìyà kúrò lórí rẹ̀?

Nígbà ó ń ṣe iṣẹ́ búburú rẹ̀,

nígbà náà jẹ́ inú rẹ̀ ó dùn."

16 Olúwa ́ igi olifi

pẹ̀èso rẹ ó dára ojú.

Ṣùgbọ́n pẹ̀ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ìjì líle

̀wọ́-iná ni yóò sun ún

àwọn ̀ka rẹ̀ yóò di gígé kúrò.

17 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ó ti kéde ibi , nítorí ilé Israẹli àti Juda ti ṣe ohun ibi, wọ́n ti inú mi, wọ́n ti ru ìbínú mi sókè nípa sísun tùràrí si Baali.

̀tẹ̀ Jerusalẹmu

18 Nítorí Olúwa fi ̀tẹ̀ wọn hàn mo mọ̀ ́n; nítorí àsìkò náà ó fi ohun wọ́n ń ṣe hàn . 19 Mo ti dàbí ̀dọ́-àgùntàn jẹ́́jẹ́ a lọ fún pípa; n mọ̀ wọ́n ti gbìmọ̀ búburú mi :

"Jẹ́ a run igi àti èso rẹ̀;

jẹ́ a e kúrò orí ilẹ̀ alààyè,

a rántí orúkọ rẹ̀ mọ́."

20 Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ó ń ṣe ìdájọ́ òdodo,

ó ń ṣe àyẹ̀̀àti ọkàn,

jẹ́ n ̀san rẹ lórí wọn;

nítorí ìwọ ni mo fi ̀rọ̀ mi lọ́wọ́.

21 "Nítorí náà, èyí ni ohun Ọlọ́run sọ nípa àwọn arákùnrin Anatoti wọ́n ń lépa ̀rẹ̀, wọ́n ń , ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ orúkọ Olúwa, bẹ́̀ kọ́ ìwọ ó láti ọwọ́ wa.22 Nítorí náà, èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ , Èmi yóò ìyà jẹ wọ́n, àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọn yóò tipasẹ̀ idà , ìyàn yóò pa àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn. 23 ṣẹ́ohunkóhun sílẹ̀ fún wọn nítorí èmi yóò ibi sórí àwọn ènìyàn Anatoti ọdún ìbẹ̀wọn.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também