Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 38

Wọ́n sọ Jeremiah sínú kànga gbígbẹ

1 Ṣefatia ọmọ Mattani, Gedaliah ọmọ Paṣuri, Jehukali ọmọ Ṣelemiah, àti Paṣuri ọmọ Malkiah, gbọ́ ohun Jeremiah ń sọ fún àwọn ènìyàn nígbà ó sọ , 2 "Èyí ni ohun Olúwa : Ẹnikẹ́ni dúró nínú ìlú yìí yóò nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn; ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni lọ Babeli yóò ; yóò àsálà, yóò .3 Àti èyí ni ohun Olúwa : Ìdánilójú a ó fi ìlú náà ọwọ́ àwọn ọmọ-ogun ọba Babeli; yóò wa nígbèkùn.’ "

4 Nígbà náà ni àwọn ìjòyè fún ọba , "Ó yẹ a pa ọkùnrin yìí; ó ń ìrẹ̀wẹ̀àwọn ọmọ-ogun tókù nínú ìlú pẹ̀gbogbo àwọn ènìyàn nípa ohun ó ń sọ fún wọn. Ọkùnrin yìí fẹ́ ìre fún àwọn ènìyàn ṣe ìparun."

5 Sedekiah ọba , "Ó lọ́wọ́ yín. Ọba ṣe ohunkóhun láti takò yín."

6 Wọ́n gbé Jeremiah sọ sínú ihò Malkiah, ọmọ ọba, ó àgbàlá ilé túbú; wọ́n fi okùn sọ Jeremiah kalẹ̀ ìsàlẹ̀ ihò; ṣí omi nínú ihò náà ṣe ẹrọ̀fọ̀, Jeremiah sínú ẹrọ̀fọ̀ náà.

7 Ṣùgbọ́n, Ebedimeleki, ará Kuṣi ìjòyè nínú ààfin ọba gbọ́ wọ́n ti ju Jeremiah sínú kànga. Nígbà ọba jókòó ẹnu-bodè Benjamini. 8 Ebedimeleki jáde kúrò láàfin ọba, ó sọ fún un , 9 "Olúwa mi ọba, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ti ṣe ohun búburú Jeremiah wòlíì Ọlọ́run. Wọ́n ti gbé e sọ sínú kànga níbi oúnjẹ kankan nínú ìlú mọ́."

10 Nígbà náà ni ọba pàṣẹ fún Ebedimeleki ará Kuṣi , "ọgbọ̀n ọkùnrin láti ibí pẹ̀rẹ, fa wòlíì Jeremiah sókè láti inú ihò, ó ."

11 Ebedimeleki àwọn ọkùnrin náà pẹ̀rẹ̀, wọ́n lọ sínú yàrá kan nínú ààfin ọba. Ó àwọn aṣọ àkísà àti okùn tọ Jeremiah lọ nínú kànga. 12 Ebedimeleki ará Kuṣi sọ fún Jeremiah , "Fi àkísà àti okùn bọ abẹ́ abíyá rẹ, Jeremiah ṣe bẹ́̀." 13 Báyìí ni wọ́n ṣe fi okùn yọ Jeremiah jáde, wọ́n mu un gòkè láti inú ihò , Jeremiah àgbàlá ilé túbú.

Sedekiah bi Jeremiah lẹ́̀kan i

14 Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ pe, Jeremiah òjíṣẹ́ Ọlọ́run àti láti un ẹnu ibodè kẹta nílé Olúwa. Ọba sọ fún Jeremiah , "Èmi yóò bi ́ ohun kan; ṣe fi ohun kan pamọ́ fún mi."

15 Jeremiah sọ fún Sedekiah , "mo fún èsì, ṣé o nípa ? mo gbà ́ nímọ̀ràn, o gbọ́ tèmi."

16 Ṣùgbọ́n ọba Sedekiah búra ìkọ̀kọ̀ fún Jeremiah , "Dájúdájú Olúwa ti ń bẹ, ẹni ó fún wa ̀, èmi nípa ́ tàbí ́ fún àwọn ń lépa ̀rẹ."

17 Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún Sedekiah , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run alágbára, Ọlọ́run Israẹli : Àyàfi o jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn olóyè ọba Babeli, a ó ̀rẹ àti ìlú yìí di jíjó iná; ìwọ àti ilé rẹ yóò láààyè. 18 Ṣùgbọ́n o jọ̀wọ́ ara rẹ fún àwọn ìjòyè ọba Babeli, a ó fa ìlú yìí ọwọ́ àwọn Babeli. Wọn yóò fi iná sun ún, ìwọ gan an le mọ́ wọn lọ́wọ́.’ "

19 Ọba Sedekiah sọ fún Jeremiah , "ń bẹ̀àwọn Júù ti sálọ ilẹ̀ Babeli, nítorí àwọn ará Babeli wọn lọ́wọ́ láti fìyà jẹ ."

20 Jeremiah dáhùn , "Wọn fi ́ e lọ́wọ́. Pa ̀rọ̀ Olúwa mọ́ nípa ṣíṣe ohun mo sọ fún ; yóò dára fún , ̀rẹ yóò . 21 Ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ láti jọ̀wọ́ ara rẹ, èyí ni ohun Olúwa ti fihàn . 22 Gbogbo àwọn obìnrin tókù ààfin ọba Juda ni wọn yóò jáde fún àwọn ìjòyè ọba Babeli. Àwọn obìnrin náà yóò sọ fún :

" Àwọn ̀rẹ́ rẹ tàn ́ jẹ,

wọ́n borí rẹ.

Ẹsẹ̀ rẹ sínú ẹrọ̀fọ̀;

àwọn ̀rẹ́ rẹ ti fi ́ sílẹ̀.’

23 "Wọn yóò àwọn ìyàwó àti ọmọ rẹ Babeli. Ìwọ gan an bọ́ níbẹ̀, ọba Babeli yóò , wọn yóò ìlú yìí kanlẹ̀."

24 Nígbà náà ni Sedekiah sọ fún Jeremiah , "ṣe jẹ́ ẹnikẹ́ni mọ̀ nípa ̀rọ̀ yìí, tàbí o . 25 àwọn ìjòyè mọ̀ mo sọ̀rọ̀, wọ́n , Sọ fún wa ohun o ọba sọ tàbí ohun ọba sọ fún ; ṣe fi pamọ́ fún wa tàbí a pa ́,’ 26 nígbà náà o sọ fún wọn, ń bẹ ọba láti jẹ́ n padà lọ ilé Jonatani láti lọ síbẹ̀.’ "

27 Gbogbo àwọn olóyè ̀dọ̀ Jeremiah láti bi í léèrè, ó sọ gbogbo ohun ọba ó sọ. Wọn sọ ohunkóhun mọ́, nítorí ẹni ó gbọ́ ̀rọ̀ òun àti ọba jọ sọ.

28 Jeremiah nínú àgbàlá àwọn ̀ṣọ́ títí di ọjọ́ wọ́n fi Jerusalẹmu:

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também