Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 24

Agbọ̀n èso ̀pọ̀tọ́ méjì

1 Lẹ́yìn Nebukadnessari ọba Babeli ti Jekoniah ọmọ Jehoiakimu ọba Juda àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn oníṣọ̀àti oníṣẹ́ ọwọ́ ti Juda lọ ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ ilẹ̀ àjèjì Babeli tán. Olúwa fi agbọ̀n èso ̀pọ̀tọ́ méjì hàn a gbé iwájú pẹpẹ Olúwa. 2 Agbọ̀n kan ni èso ̀pọ̀tọ́ ó dára èyí ó tètè pọ́n; èkejì èso ̀pọ̀tọ́ ó burú rékọjá le è ṣe é jẹ.

3 Nígbà náà ni Olúwa bi , "ni ìwọ Jeremiah?"

Mo dáhùn pe, "Èso ̀pọ̀tọ́." Mo dáhùn. "Èyí ó dáradára púpọ̀, ṣùgbọ́n èyí ó burú burú rékọjá ṣe é jẹ."

4 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ : 5 "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli : Gẹ́gẹ́ àwọn èso ̀pọ̀tọ́ dáradára yìí ni Èmi yóò ka àwọn wọ́n lọ ilẹ̀ àjèjì láti Juda èmi rán jáde kúrò ibí yìí lọ ilẹ̀ àwọn ará Kaldea. 6 Ojú mi yóò máa ṣọ́ wọn lọ fún rere, Èmi yóò gbé wọn , n wọn lulẹ̀. Èmi yóò gbìn wọ́n, n wọ́n tu. 7 Èmi yóò fún wọn ọkàn láti mọ̀ , "Èmi ni Olúwa." Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi; Èmi ni yóò jẹ́ Ọlọ́run wọn; nítorí wọn yóò padà sọ́dọ̀ mi pẹ̀gbogbo ọkàn wọn.

8 " Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ èso ̀pọ̀tọ́ dára, ó burú ṣe é jẹ,ni Olúwa , bẹ́̀ ni Èmi yóò ṣe pẹ̀Sedekiah ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀ àti àwọn ó yẹ Jerusalẹmu, yálà wọ́n lórí ilẹ̀ yìí tàbí wọ́n ń gbé Ejibiti. 9 Èmi yóò sọ wọ́n di ìwọ̀àti ẹni ibi nínú gbogbo ìjọba ayé, láti di ẹni ìfibú àti ẹni òwe, ẹni ̀sín, àti ẹni ̀gàn ibi gbogbo Èmi ó wọn . 10 Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn wọn, títí gbogbo wọn yóò parun lórí ilẹ̀ a fún wọn àti fún àwọn baba wọn.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também