Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 52

Ìṣubú Jerusalẹmu

1 Sedekiah jẹ́ ọmọ ọdún mọ́kànlélógún nígbà ó jẹ ọba. Ọdún mọ́kànlá fi jẹ ọba Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Hamutali ọmọ Jeremiah; láti Libina ti . 2 52.2: 2Ọb 24.18–25.30; 2Ki 36.11-13.Ó ṣe búburú ojú Olúwa gẹ́gẹ́ Jehoiakimu ti ṣe. 3 Nítorí ìbínú Olúwa ni gbogbo èyí ṣe ṣẹlẹ̀ Jerusalẹmu àti Juda àti ìkẹyìn. Ó gbà wọ́n gbọ́ iwájú rẹ̀.

Sedekiah ṣọ̀tẹ̀ ọba Babeli.

4 Nígbà ó di ọdún kẹsànán ti Sedekiah ń ṣe ìjọba ọjọ́ kẹwàá, oṣù kẹwàá Nebukadnessari ọba Babeli lọ Jerusalẹmu pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, wọ́n pàgọ́ ̀yìn odi ìlú náà; wọ́n mọ odi yíká rẹ̀. 5 Ìlú náà lábẹ́ ìhámọ́ títí di ọdún kọkànlá ọba Sedekiah.

6 ọjọ́ kẹsànán, oṣù mẹ́rin ìyàn ìlú náà ti burú ibi oúnjẹ kankan mọ́ fún àwọn ènìyàn láti jẹ. 7 Bákan náà, odi ìlú náà ti ya àwọn ọmọ-ogun sálọ. Wọn fi ìlú náà sílẹ̀ òru nípa ojú ̀láàrín odi méjèèjì lẹ́bàá ọgbà ọba. ó tilẹ̀ jẹ́ , àwọn ará Babeli yìí ìlú náà . Wọ́n gba aginjù lọ. 8 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ-ogun Babeli lépa ọba Sedekiah wọ́n le ni pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko. Gbogbo àwọn ọmọ-ogun pínyà, kúrò ̀dọ̀ rẹ̀ wọ́n túká. 9 Wọ́n mu ìgbèkùn.

Wọn un lọ ̀dọ̀ ọba Babeli, Ribla ilẹ̀ Hamati níbẹ̀ ni ó ti ṣe ìdájọ́ lórí rẹ̀. 10 Ribla ni ọba Babeli ti pa ọmọkùnrin Sedekiah lójú rẹ̀; ó tún pa gbogbo àwọn aláṣẹ Juda. 11 Lẹ́yìn náà, ọba Babeli yọ Sedekiah ojú, o fi ̀wọ̀n é, ó gbe e lọ Babeli níbi ó ti fi sínú ọgbà ̀wọ̀n títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.

12 ọjọ́ kẹwàá oṣù karùn-ún, ó jẹ́ ọdún kọkàndínlógún Nebukadnessari ọba Babeli, ni Nebusaradani balógun ìṣọ́ Jerusalẹmu. 13 Ó dáná sun pẹpẹ Olúwa, ààfin ọba àti gbogbo àwọn ilé Jerusalẹmu. Ó dáná sun gbogbo àwọn ilé ńlá ńlá. 14 Gbogbo àwọn ogun Babeli, ó lọ́dọ̀ olórí ̀ṣọ́, ògiri ó Jerusalẹmu lulẹ̀. 15 Nebusaradani balógun ìṣọ́ gbogbo àwọn tálákà àti gbogbo àwọn ó ìlú, ìgbèkùn lọ Babeli, pẹ̀àwọn ó ya lọ, ó ya tọ ọba Babeli lọ, àti ìyókù àwọn ènìyàn náà. 16 Ṣùgbọ́n Nebusaradani, balógun ìṣọ́ fi àwọn tálákà ilẹ̀ náà sílẹ̀ láti máa ṣiṣẹ́ nínú ọgbà àjàrà àti ro oko.

17 Àwọn ará Babeli fọ́ ̀wọ̀n idẹ wọ̀n-ọn-nì àti àwọn ìjókòó wọ̀n-ọn-nì, àti agbada idẹ títóbi wọ̀n-ọn-nì ń bẹ ilé Olúwa, àwọn ará Babeli fọ́ túútúú, wọ́n gbogbo idẹ náà lọ Babeli. 18 Bákan náà, wọ́n tún àwọn ìkòkò wọ̀n-ọn-nì, ọkọ́ wọ̀n-ọn-nì àti ̀fìtílà wọ̀n-ọn-nì, àwọn ọpọ́n wọ̀n-ọn-nì, ṣíbí wọ̀n-ọn-nì àti gbogbo ohun èlò idẹ wọ́n ń níbi pẹpẹ lọ. 19 Balógun ìṣọ́ náà àwokòtò wọ̀n-ọn-nì, ohun ìfọnná wọ̀n-ọn-nì, ọpọ́n wọ̀n-ọn-nì, ìkòkò wọ̀n-ọn-nì, ̀fìtílà wọ̀n-ọn-nì, ṣíbí wọ̀n-ọn-nì àti ago wáìnì wọ̀n-ọn-nì; èyí a fi wúrà àti fàdákà ṣe lọ.

20 Àwọn ̀wọ́n méjì, agbada ńlá kan àti àwọn màlúù idẹ méjìlá ó lábẹ́ ìjókòó alágbéká Solomoni ọba ṣe fún ilé Olúwa, idẹ ni gbogbo ohun èlò wọ̀nyí, ó ju èyí a wọ́n lọ. 21 ̀kọ̀̀kan nínú àwọn ̀wọ́n yìí ni ga ìwọ̀n ìgbọ̀nwọ́ méjìdínlógún; okùn ìgbọ̀nwọ́ méjìlá i . ̀kọ̀̀kan nípọn ìka mẹ́rin, wọ́n ihò nínú. 22 ̀orí idẹ kan ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún gíga, wọ́n fi èso pomegiranate ṣe ̀ṣọ́ i lára yíká. ̀wọ́n kejì pẹ̀èso pomegiranate ó jọra. 23 Pomegiranate mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn-ún ni ó àwọn ̀gbẹ́ rẹ̀. Àpapọ̀ gbogbo pomegiranate jẹ́ ọgọ́rùn-ún kan.

24 Balógun àwọn ̀ṣọ́ mu Seraiah olórí àwọn àlùfáà àti Sefaniah àlùfáà kejì àti àwọn olùṣọ́ ìloro mẹ́ta. 25 Nínú àwọn ó ilẹ̀ náà, ó ìwẹ̀kan, ó ìtọ́àwọn ológun, àti àwọn olùdámọ̀ràn ọba méje. Bákan náà, ó tún mu akọ̀olórí ogun ó ìtọ́títo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti ọgọ́ta nínú àwọn ọkùnrin rẹ̀ wọ́n ìlú náà. 26 Nebusaradani, balógun ìṣọ́ gbogbo wọn, ó wọn tọ ọba Babeli Ribla. 27 Ọba Babeli kọlù wọ́n, ó pa wọ́n Ribla ni ilẹ̀ Hamati.

Báyìí ni a Juda kúrò ilẹ̀ rẹ̀.

28 Èyí ni iye àwọn ènìyàn Nebukadnessari lọ ilẹ̀ àjèjì.

ọdún keje ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ó mẹ́tàlélógún (3,023) ará Juda.

29 ọdún kejìdínlógún Nebukadnessari

o ẹgbẹ̀rin ó méjìlélọ́gbọ̀n (832) láti Jerusalẹmu.

30 ọdún kẹtàlélógún àwọn Júù

Nebusaradani lọ ilẹ̀ àjèjì jẹ́ ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín márùn-ún (745).

Gbogbo ènìyàn ó lápapọ̀ jẹ́ ẹgbẹ̀tàlélógún (4,600).

Ìtúsílẹ̀ Jehoiakimu

31 ọdún kẹtàdínlógójì ti Jehoiakini ọba Juda ni Efili-Merodaki di ọba Babeli. Ó gbé orí Jehoiakini ọba Juda sókè, ó sílẹ̀ nínú túbú ọjọ́ kẹẹdọ́gbọ̀n oṣù kejìlá. 32 Ó ń sọ̀rọ̀ rere fún un, ó gbé ìtẹ́ rẹ̀ ga ju ìtẹ́ àwọn ọba tókù lọ ó pẹ̀rẹ̀ Babeli. 33 Nítorí náà, Jehoiakini pàrọ̀ aṣọ túbú rẹ̀, ó ń jẹun gbogbo ìgbà iwájú rẹ̀ gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀. 34 ojoojúmọ́ ni ọba Babeli ń fún Jehoiakini ìpín tirẹ̀ ó ń bẹ láààyè, títí di ọjọ́ rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também