Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 4

1 "ìwọ yóò padà, ìwọ Israẹli, padà tọ̀ ,"

ni Olúwa .

"ìwọ yóò ìríra rẹ kúrò níwájú mi,

ìwọ ó rìn kiri.

2 ó jẹ́ lóòtítọ́ àti òdodo ni ìwọ búra.

Nítòótọ́ Olúwa ti láààyè,

nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò di alábùkún fún nípasẹ̀ rẹ,

àti nínú rẹ̀ ni wọn yóò ṣògo."

3 Èyí ni ohun Olúwa fún àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu:

"gbogbo ilẹ̀ ,

o ṣe gbìn sáàrín ̀gún.

4 Kọ ara rẹ ilà Olúwa,

kọ ọkàn rẹ ilà,

̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu,

bẹ́̀ kọ́, ìbínú mi yóò ru jáde yóò iná,

nítorí ibi o ti ṣe

yóò ẹni yóò pa á.

Àjálù láti ilẹ̀ gúúsù

5 "Kéde Juda, o polongo Jerusalẹmu, o :

Fun fèrè káàkiri gbogbo ilẹ̀!’

o kígbe:

ara jọ pọ̀!

Jẹ́ a sálọ ìlú olódi.

6 Fi àmì láti sálọ Sioni hàn,

sálọ fún ààbò láìsí ìdádúró.

Nítorí èmi ó àjálù láti àríwá ,

àní ìparun ó burú jọjọ."

7 Kìnnìún ti jáde láti inú ibùgbé rẹ̀,

apanirun orílẹ̀-èdè ti jáde.

Ó ti fi ààyè rẹ̀ sílẹ̀

láti ba ilẹ̀ rẹ̀ jẹ́.

Ìlú rẹ yóò di ahoro

láìsí olùgbé.

8 Nítorí náà, gbé aṣọ ̀fọ̀ wọ̀

káàánú o pohùnréré ẹkún,

nítorí ìbínú ńlá Olúwa

ì kúrò lórí wa.

9 "ọjọ́ náà," ni Olúwa ,

"Àwọn ọba àti ìjòyè yóò pàdánù ̀wọn,

àwọn àlùfáà yóò wárìrì,

àwọn wòlíì yóò fòyà."

10 Nígbà náà ni mo , "Háà! Olúwa Olódùmarè, báwo ni ìwọ ti ṣe tan àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti Jerusalẹmu jẹ nípa sísọ , Ìwọ yóò àlàáfíà,nígbà o jẹ́ idà ̀fun wa."

11 Nígbà náà ni a ó sọ fún Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn , "̀fúùfù líle láti aṣálẹ̀ fẹ́ lu àwọn ènìyàn mi, í ṣe láti sọ di mímọ́. 12 ̀fúùfù líle ó láti ̀dọ̀ mi. Báyìí mo kéde ìdájọ́ mi lórí wọn."

13 ó! O ń bọ̀ ìkùùkuu

kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ ìjì líle

ẹṣin rẹ̀ yára ju idì lọ.

Ègbé ni fún wa àwa parun.

14 Ìwọ Jerusalẹmu, búburú kúrò lọ́kàn rẹ o .

Yóò ti pẹ́ ìwọ yóò èrò búburú ọkàn rẹ?

15 Ohùn kan ń kéde Dani

o ń kókìkí ìparun láti orí òkè Efraimu .

16 "Sọ èyí fún àwọn orílẹ̀-èdè,

kéde rẹ̀ fún Jerusalẹmu :

Ọmọ-ogun ̀ń bọ̀ láti ilẹ̀ jíjìn

wọ́n ń kígbe ogun láti dojúkọ ìlú Juda.

17 Wọ́n i ìgbà àwọn ọkùnrin ń ṣọ́ pápá,

nítorí ó ti dìtẹ̀ mi,’ "

ni Olúwa .

18 "Ìwà rẹ àti ìṣe rẹ

fa èyí

ìjìyà rẹ nìyìí.

Báwo ti ṣe korò !

Báwo ti ṣe gún ọkàn rẹ !"

19 Háà! Ìrora mi, ìrora mi!

Mo nínú ìrora.

Háà, ìrora ọkàn mi!

Ọkàn mi kìkì nínú mi,

n le è dákẹ́.

Nítorí mo ti gbọ́ ohùn ìpè,

mo ti gbọ́ igbe ogun.

20 Ìparun ń gorí ìparun;

gbogbo ilẹ̀ náà ṣubú sínú ìparun

lọ́gán ni a àwọn àgọ́ mi,

ó jẹ́ ohun ààbò mi níṣẹ́kan.

21 Yóò ti pẹ́ , èmi yóò ogun

èmi yóò gbọ́ ìró fèrè?

22 "Aṣiwèrè ni àwọn ènìyàn mi;

wọn mọ̀ .

Wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n ọmọ;

wọ́n jẹ́ aláìlóye.

Wọ́n mọ ibi ni ṣíṣe;

wọn mọ a ti í ṣe rere."

23 Mo bojú wo ayé,

ó júujùu, ó ṣófo

àti ̀run,

ìmọ́lẹ̀ wọn ṣí.

24 Mo wo àwọn òkè ńlá,

wọ́n wárìrì;

gbogbo òkè kéékèèké jẹ̀jẹ̀.

25 Mo yíká n ẹnìkan;

gbogbo ẹyẹ ojú ̀run ti lọ.

26 Mo bojú , ilẹ̀ eléso, ó di aṣálẹ̀

gbogbo àwọn ìlú inú rẹ̀ ṣubú sínú ìparun

níwájú Olúwa àti níwájú ríru ìbínú rẹ̀.

27 Èyí ni ohun Olúwa :

"Gbogbo ìlú náà yóò di ahoro,

síbẹ̀ èmi yóò pa á run pátápátá.

28 Nítorí náà, ayé yóò pohùnréré ẹkún

àwọn ̀run lókè yóò ṣú òòkùn

nítorí mo ti sọ, mo ti pète rẹ̀

mo ti pinnu, n yóò i padà."

29 Nípa ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin àti àwọn tafàtafà

gbogbo ìlú yóò sálọ.

̀pọ̀ sálọ sínú igbó;

̀pọ̀ yóò gun orí àpáta lọ.

Gbogbo ìlú náà di ahoro;

ṣí ẹnìkan nínú rẹ̀.

30 ni ò ń ṣe, ìwọ o ti di ìjẹ tán?

Ìwọ ìbá wọ ara rẹ aṣọ òdodo

o fi wúrà ṣe ara rẹ lọ́ṣọ̀́.

Àwọn olólùfẹ́ rẹ kẹ́gàn rẹ;

wọ́n ń lépa ̀rẹ.

31 Mo gbọ́ ìró kan i igbe obìnrin ń rọbí,

ó ń rọbí, ìrora i abiyamọ

ọmọbìnrin Sioni ń pohùnréré ẹkún ara rẹ̀.

ó na ọwọ́ rẹ̀ ó ,

"Kíyèsi i mo gbé,

nítorí a ti fi ̀mi àwọn apani lọ́wọ́."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também