Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 45

Ìlérí Ọlọ́run fún Baruku

1 Èyí ni ̀rọ̀ Jeremiah wòlíì sọ fún Baruku ọmọ Neriah ọdún kẹrin ti Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda. Lẹ́yìn Baruku ti kọ sínú ìwé kíká àwọn ̀rọ̀ Jeremiah ti ń sọ: 2 "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ fún , Baruku. 3 Ìwọ , Ègbé ni fún mi! Olúwa ti fi ìbànújẹ́ kún ìrora mi, àárẹ̀ mi nínú ̀dùn mi, èmi ìsinmi.’ " 4 Olúwa sọ èyí fún un, "Èyí ni Ọlọ́run sọ: Èyí èmi ti kọ́ ni èmi yóò lulẹ̀, àti èyí èmi ti gbìn ni èmi yóò fàtu, àní orí gbogbo ilẹ̀. 5 Ṣé ìwọ ń ohun títóbi fún ara rẹ? Nítorí náà, ṣe wọn. Èmi yóò ibi orí àwọn ènìyàn gbogbo ni Olúwa , ṣùgbọ́n níbikíbi ìwọ lọ ni èmi yóò jẹ́ o àsálà pẹ̀̀rẹ.’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também