Pular para o conteúdo
Publicidade

Obadiah 1

1 Ìran ti Obadiah.

1-21: Isa 34; 63.1-6; Jr 49.7-22; El 25.12-14; 35; Am 1.11-12; Ml 1.2-5. Èyí ni Olúwa Olódùmarè nípa Edomu.

Àwa ti gbọ́ ohùn kan láti ̀dọ̀ Olúwa ,

a ti rán ikọ̀ kan gbogbo kèfèrí láti sọ ,

"dìde, jẹ́ a dìde ogun i."

2 "Kíyèsi i, Èmi yóò sọ ́ di kékeré láàrín àwọn kèfèrí;

ìwọ yóò di gígàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.

3 Ìgbéraga àyà rẹ ti tàn ́ jẹ,

ìwọ ń gbé inú pálapàla àpáta,

o kọ́ ibùgbé rẹ ibi gíga,

ìwọ nínú ọkàn rẹ ,

Ta ni yóò mi sọ̀kalẹ̀?’

4 ìwọ tilẹ̀ gbé ara rẹ ga ẹyẹ idì,

ìwọ tilẹ̀ tẹ́ ìtẹ́ rẹ àárín àwọn ìràwọ̀,

láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀ kalẹ̀,"

ni Olúwa .

5 "àwọn olè tọ̀ ́ ,

àwọn ọlọ́ṣà òru,

Háà! Irú ìparun wo dúró ́,

wọn ha jalè wọ́n ti fẹ́?

àwọn ń èso àjàrà tọ̀ ́ ,

wọn ha ni fi èso àjàrà díẹ̀ sílẹ̀?

6 Báwo ni a ṣe ṣe àwárí nǹkan Esau,

a ohun ìní ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ jáde.

7 Gbogbo àwọn ẹni ìmùlẹ̀ rẹ

ti ìpẹ̀kun ilẹ̀ rẹ,

àwọn ̀rẹ́ rẹ ti tàn ́ jẹ, wọ́n ti borí rẹ;

àwọn jẹ oúnjẹ rẹ dẹ pàkúté ́,

ṣùgbọ́n ìwọ òye rẹ̀."

8 Olúwa , "ọjọ́ náà,

Èmi yóò ha pa àwọn ọlọ́gbọ́n Edomu run,

àti àwọn amòye run kúrò òkè Esau?

9 A ó ṣe ̀ba àwọn jagunjagun rẹ, ìwọ Temani,

gbogbo àwọn orí òkè Esau

a ó kúrò nínú ìpànìyàn náà.

10 Nítorí ìwà ipá Jakọbu arákùnrin rẹ,

ìtìjú yóò ,

a ó pa run títí láé.

11 ọjọ́ ìwọ dúró apá kan,

ọjọ́ àlejò ogún rẹ lọ,

àwọn àjèjì wọ ibodè rẹ,

wọ́n sẹ́ kèké lórí Jerusalẹmu,

ìwọ náà ̀kan nínú wọn.

12 Ìwọ fi ojú kéré arákùnrin rẹ,

àkókò ìbànújẹ́ rẹ̀

ìwọ yọ̀ lórí àwọn ọmọ Juda,

ọjọ́ ìparun wọn

ìwọ gbéraga púpọ̀

ọjọ́ wàhálà wọn.

13 Ìwọ wọ inú ibodè àwọn ènìyàn mi lọ,

ọjọ́ àjálù wọn.

Ìwọ fojú wọn mọ́lẹ̀

nínú ìdààmú wọn, ọjọ́ àjálù wọn.

Ìwọ ẹrù wọn ,

ọjọ́ ìpọ́njú wọn.

14 Ìwọ dúró ìkóríta ̀

láti àwọn tirẹ̀ ti sálà kúrò.

Ìwọ fa àwọn ṣẹ́nínú

wọn lélẹ̀ ọjọ́ wàhálà wọn.

15 "Nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ etílé

lórí gbogbo àwọn kèfèrí.

ìwọ ti ṣe, bẹ́̀ ni a ó ṣe ìwọ náà;

̀san rẹ yóò yípadà orí ara rẹ.

16 Gẹ́gẹ́ ìwọ̀ ṣe mu lórí òkè mímọ́ mi,

bẹ́̀ ni gbogbo kèfèrí yóò máa mu títí;

wọn yóò mu ún àmutẹ́rùn

wọn yóò ẹni wọn mu ún .

17 Ṣùgbọ́n ìgbàlà yóò lórí òkè Sioni,

wọn yóò jẹ́ mímọ́,

àti ilé Jakọbu yóò ìní wọn.

18 Ilé Jakọbu yóò jẹ́ iná

àti ilé Josẹfu ọwọ́ iná

ilé Esau yóò jẹ àgékù koríko

wọn yóò fi iná i,

wọn yóò jo run.

yóò ẹni yóò ilé Esau."

Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀.

19 Àwọn ará gúúsù yóò ni òkè Esau,

àwọn ará ẹsẹ̀ òkè yóò ni

ilẹ̀ àwọn ará Filistini ìní.

Wọn yóò ni oko Efraimu àti Samaria;

Benjamini yóò Gileadi ìní.

20 Àwọn ìgbèkùn Israẹli ó Kenaani

yóò ni ilẹ̀ títí Sarefati;

àwọn ìgbèkùn láti Jerusalẹmu ó Sefaredi

yóò ni àwọn ìlú gúúsù ìní.

21 Àwọn ń gba ni yóò gòkè Sioni

láti jẹ ọba orí àwọn òkè Esau.

Ìjọba náà yóò jẹ́ ti Olúwa.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também

Obadias
Ver todos os capítulos de Obadias