Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 51

1 Ohùn ti Olúwa nìyìí:

"ó èmi yóò ru afẹ́fẹ́ apanirun sókè

Babeli àti àwọn ènìyàn Lebikamai,

2 Èmi yóò rán àwọn àjèjì ènìyàn Babeli

láti fẹ́ , yóò sọ ilẹ̀ rẹ̀ di òfo;

wọn yóò takò ó gbogbo ̀

ọjọ́ ìparun rẹ̀.

3 ṣe jẹ́ tafàtafà yọ ọfà rẹ̀,

jáde tàbí ó di ìhámọ́ra rẹ̀.

ṣe àwọn ̀dọ́mọkùnrin ;

pátápátá ni o pa àwọn ọmọ-ogun rẹ̀.

4 Gbogbo wọn ni yóò ṣubú Babeli,

wọn yóò fi ara pa yánnayànna òpópónà.

5 Nítorí Juda àti Israẹli ni

Ọlọ́run wọn í ṣe Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

gbàgbọ́ o tilẹ̀ jẹ́ ilé wọn

kún fún kìkì ̀bi níwájú ẹni mímọ́ Israẹli.

6 51.6,9,45: Jr 50.8; 2Kọ 6.17; If 18.4. "kúrò Babeli!

àsálà fún ̀rẹ!

ṣe ṣègbé torí ̀ṣẹ̀ rẹ.

Àsìkò àti gbẹ̀san Olúwa ni èyí;

yóò sán fún òun gẹ́gẹ́ ó ti tọ́.

7 51.7-8: Jr 25.15; If 14.8,10; 16.19; 17.4; 18.3. Ife wúrà ni Babeli ọwọ́ Olúwa;

ó sọ gbogbo ayé di ̀mùtí.

Gbogbo orílẹ̀-èdè mu ọtí rẹ̀,

wọ́n ti ya òmùgọ̀ kalẹ̀.

8 Babeli yóò ṣubú lójijì, yóò fọ́.

hu fun un!

ìkunra fún ìrora rẹ,

bóyá yóò le wo ́ sàn.

9 " À ti wo Babeli sàn,

ṣùgbọ́n sàn, jẹ́ a fi sílẹ̀,

oníkálùkù lọ ilẹ̀ rẹ̀ torí ìdájọ́ rẹ̀ gòkè,

ó ga àní títí òfúrufú.

10 " Olúwa ti wa láre,

jẹ́ a sọ ́ Sioni ohun Olúwa

Ọlọ́run wa ti ṣe.

11 "Ṣe ọfà rẹ mímú,

àpáta!

Olúwa ti ru ọba Media sókè,

nítorí ète rẹ̀ ni láti pa Babeli run.

Olúwa yóò gbẹ̀san, àní ̀san fún tẹmpili rẹ̀.

12 Gbé àsíá sókè odi Babeli!

ṣe àwọn ọmọ-ogun gírí,

pín àwọn olùṣọ́ káàkiri,

ṣètò àwọn yóò pamọ́

Olúwa! Yóò gbé ète rẹ̀ jáde,

òfin rẹ̀ àwọn ará Babeli.

13 51.13: If 17.1. Ìwọ o gbé lẹ́bàá odò púpọ̀,

o ni ̀rọ̀ púpọ̀; ìgbẹ̀yìn rẹ ti ,

àní àsìkò láti kúrò!

14 Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra fún ara rẹ̀,

Èmi yóò fún ènìyàn gẹ́gẹ́ ̀pọ̀ eṣú,

wọn yóò yọ ayọ̀, ìṣẹ́gun lórí rẹ.

15 "Ó ilẹ̀ nípa agbára rẹ̀,

o ilẹ̀ ayé pẹ̀ọgbọ́n rẹ̀,

o tẹ́ ̀run pẹ̀ìmọ̀ rẹ̀.

16 Nígbà ará omi ̀run

ó òfúrufú ru sókè láti ìpẹ̀kun ayé.

Ó rán mọ̀nàmọ́pẹ̀òjò,

ó afẹ́fẹ́ jáde láti ilé ìṣúra rẹ̀.

17 "Olúkúlùkù ènìyàn ni lọ́pọlọ ìmọ̀,

olúkúlùkù alágbẹ̀dẹ ni a ìtìjú nípa òrìṣà rẹ̀.

Àwọn ère rẹ jẹ́ ̀tàn;

wọn èémí nínú.

18 Asán ni wọ́n, àti iṣẹ́ ìsìnà,

nígbà ìbẹ̀wọn, wọn ó ṣègbé.

19 Ẹni ó jẹ́ ìpín Jakọbu ìwọ̀nyí;

nítorí òun ni ó ohun gbogbo,

àti gbogbo àwọn ̀ajogún,

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

20 "Ìwọ ni kùmọ̀ ogun ohun èlò ogun mi,

ohun èlò ìjà mi, pẹ̀rẹ èmi ó fọ́ orílẹ̀-èdè túútúú,

èmi ó àwọn ilé ọba jẹ́.

21 Pẹ̀rẹ, èmi ó pa ẹṣin àti ẹni ó gùn ún pẹ̀rẹ̀;

èmi ó ba kẹ̀kẹ́ ogun jẹ́ pẹ̀

èmi ó pa awakọ̀,

22 pẹ̀rẹ, mo pa ọkùnrin àti obìnrin,

pẹ̀rẹ, mo pa àgbàlagbà àti ọmọdé,

pẹ̀rẹ, mo pa ̀dọ́mọkùnrin àti ̀dọ́mọbìnrin.

23 Èmi yóò fi ́ fọ́ olùṣọ́-àgùntàn,

àti agbo àgùntàn rẹ̀ túútúú,

èmi yóò fi ́ fọ́ àgbẹ̀ àti àjàgà màlúù túútúú,

èmi yóò fi ́ fọ́ baálẹ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀ túútúú.

24 "ojú rẹ, èmi yóò san án fún Babeli àti gbogbo àwọn olùgbé inú rẹ̀ fún gbogbo ibi wọ́n ti ṣe Sioni,"

ni Olúwa .

25 "Mo lòdì , ìwọ òkè apanirun

ìwọ ti ba gbogbo ayé jẹ́,"

ni Olúwa .

"Èmi ó na ọwọ́ mi ,

èmi yóò kúrò lórí àpáta,

Èmi yóò sọ ́ dàbí òkè a ti .

26 A òkúta kankan láti

̀dọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ igun ilé tàbí

fún ìpínlẹ̀ nítorí ìwọ yóò di

ahoro títí ayé,"

Olúwa .

27 "Gbé àsíá sókè ilẹ̀ náà!

Fọn ìpè láàrín àwọn orílẹ̀-èdè!

Sọ àwọn orílẹ̀-èdè di mímọ́ sórí rẹ̀,

pe àwọn ìjọba yìí láti dojúkọ ́:

Ararati, Minini àti Aṣkenasi.

Yan olùdarí ogun láti kọlù ú,

rán àwọn ẹṣin i ̀pọ̀ eṣú.

28 Sọ àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀àwọn ọba Media di mímọ́ sórí rẹ̀,

àwọn baálẹ̀ rẹ̀, àti gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀,

àti gbogbo orílẹ̀-èdè wọ́n jẹ ọba lórí.

29 Ilẹ̀ wárìrì síyìn-ín sọ́hùn-ún,

nítorí ète Olúwa, Babeli dúró,

láti ba ilẹ̀ Babeli jẹ́ lọ́

ẹnikẹ́ni gbé inú rẹ̀ mọ́.

30 Gbogbo àwọn jagunjagun

Babeli dáwọ́ ìjà dúró sínú àgọ́ wọn.

Agbára wọn ti tán, wọ́n ti dàbí obìnrin.

Ibùgbé rẹ̀ ni a ti dáná sun,

gbogbo irin ẹnu-ọ̀wọn ti di fífọ́.

31 Ìránṣẹ́ kan ń tẹ̀òmíràn

láti sọ fún ọba Babeli

gbogbo ìlú rẹ̀ ni a ti ìgbèkùn.

32 Odò ó sàn kọjá sàn mọ́

ilẹ̀ àbàtà gbiná, àwọn jagunjagun wárìrì."

33 Ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run àwọn ọmọ Israẹli sọ nìyìí:

"Ọmọbìnrin Babeli dàbí ìpakà àsìkò láti kórè rẹ̀ pẹ́ mọ́."

34 "Nebukadnessari ọba Babeli jẹ run,

ó ti ìdààmú wa,

ó ti sọ di àgbá òfìfo.

Gẹ́gẹ́ ejò, ó ti gbé wa .

Ó fi oúnjẹ àdídùn wa kún inú rẹ̀,

lẹ́yìn náà ni ó pọ̀ jáde.

35 gbogbo ìparun ó ṣe ẹran-ara wa lórí Babeli,"

èyí àwọn ibùgbé Sioni .

"̀jẹ̀ wa lórí gbogbo àwọn ń gbé Babeli,"

ni Jerusalẹmu .

36 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa :

"ó, èmi yóò ́ lẹ́yìn lórí

ohun o fẹ́ ṣe. Èmi ó gbẹ̀san,

èmi yóò omi Òkun rẹ̀ àti orísun omi rẹ̀ gbẹ.

37 Babeli yóò parun pátápátá,

yóò di ihò àwọn akátá,

ohun ̀àti àbùkù, ibi ènìyàn gbé.

38 Àwọn ènìyàn inú rẹ̀ ramúramù

ọmọ kìnnìún.

39 Ṣùgbọ́n nígbà ọkàn wọn ru sókè,

èmi yóò ṣe àsè fún wọn,

èmi yóò jẹ́ wọn mutí

wọn yóò máa kọ fun ̀rín,

lẹ́yìn náà, wọn yóò sun oorun, wọn yóò ,"

ni Olúwa .

40 "Èmi yóò wọ́n lọ gẹ́gẹ́ ̀dọ́-àgùntàn

a fẹ́ pa, gẹ́gẹ́ àgbò àti ewúrẹ́.

41 "Báwo ni Ṣeṣaki yóò ṣe mímú, ìfọ́nnu gbogbo àgbáyé.

Irú ìpayà wo ni yóò

Babeli láàrín àwọn orílẹ̀-èdè!

42 Òkun yóò ru borí Babeli,

gbogbo rírú rẹ̀ yóò borí Babeli.

43 Àwọn ìlú rẹ̀ yóò di ahoro,

ilẹ̀ ó gbẹ, ilẹ̀ ènìyàn

gbé ènìyàn rin ìrìnàjò.

44 Èmi yóò fi ìyà jẹ Beli ti Babeli

àti èmi yóò jẹ́ ó pọ gbogbo àwọn ohun ó gbé .

Àwọn orílẹ̀-èdè yóò jùmọ̀ sàn lọ pọ̀ ̀dọ̀ rẹ̀ mọ́.

òótọ́ odi Babeli yóò .

45 "jáde kúrò nínú rẹ̀

̀yin ènìyàn mi!

àsálà fún ̀rẹ!

fún ìbínú ńlá Olúwa.

46 ṣe jẹ́ ọkàn rẹ dàrú

tàbí o bẹ̀nígbà

a gbọ́ àhesọ ̀rọ̀ ilẹ̀ wa;

àhesọ ̀rọ̀ kan ọdún yìí,

òmíràn ọdún mìíràn àhesọ ̀rọ̀ ni ti ìwà ipá

ilẹ̀ náà àti aláṣẹ kan aláṣẹ kejì.

47 Nítorí ìgbà náà yóò dandan

nígbà èmi yóò fi ìyà jẹ àwọn òrìṣà Babeli;

gbogbo ilẹ̀ rẹ̀ ni a ó dójútì

gbogbo àwọn a pa yóò ṣubú àárín rẹ̀.

48 ̀run àti ayé àti gbogbo ohun ó nínú wọn,

yóò kọrin lórí Babeli:

nítorí àwọn afiniṣèjẹ yóò sórí rẹ̀ láti àríwá,"

ni Olúwa .

49 "Babiloni gbọdọ̀ ṣubú nítorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni Israẹli,

gẹ́gẹ́ àwọn ti a pa gbogbo ayé nítorí Babeli.

50 ̀yin ó ti bọ́ lọ́wọ́ idà, lọ, dúró.

rántí Olúwa òkèrè,

jẹ́ Jerusalẹmu ọkàn yín."

51 "Ojú , nítorí àwa ti gbọ́ ̀gàn:

ìtìjú ti lójú

nítorí àwọn àjèjì sórí ohun mímọ́ ilé Olúwa."

52 "Nítorí náà, ó, ọjọ́ ń bọ̀," ni Olúwa ,

"èmi yóò ṣe ìbẹ̀lórí àwọn ère fínfín rẹ̀,

àti àwọn ó gbọgbẹ́

yóò máa kérora gbogbo ilẹ̀ rẹ̀.

53 Babeli tilẹ̀ gòkè lọ ̀run,

ó ṣe ìlú olódi òkè agbára rẹ,

síbẹ̀ àwọn afiniṣèjẹ yóò ti ̀dọ̀ mi tọ̀ ́ ,"

Olúwa .

54 "Ìró igbe láti Babeli,

àti ìparun láti ilẹ̀ àwọn ará Kaldea!

55 Nítorí Olúwa ti ṣe Babeli ìjẹ,

ó ti pa ohun ńlá run kúrò nínú rẹ̀;

àwọn ̀wọn ń bi omi púpọ̀, a gbọ́ ariwo ohùn wọn.

56 Nítorí afiniṣèjẹ sórí rẹ̀,

àní sórí Babeli;

a àwọn akọni rẹ̀, a ṣẹ́ gbogbo ọrun wọn:

nítorí Ọlọ́run ̀san ni Olúwa,

yóò san án nítòótọ́.

57 Èmi ó àwọn ìjòyè rẹ̀ ̀mùtí,

àti àwọn ọlọ́gbọ́n rẹ̀

àti àwọn baálẹ̀ rẹ̀, àti àwọn akọni rẹ̀,

wọn ó sun oorun láéláé, wọn ó mọ́,"

ọba , ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

58 Báyìí Olúwa àwọn ọmọ-ogun :

"Odi Babeli gbígbòòrò a ó lulẹ̀ pátápátá,

ẹnu-bodè gíga rẹ̀ a ó fi iná sun:

bẹ́̀ àwọn ènìyàn ti ṣiṣẹ́ lásán,

àti àwọn orílẹ̀-èdè ti ṣiṣẹ́ fún iná,

àárẹ̀ wọn."

59 ̀rọ̀ Jeremiah wòlíì pàṣẹ fún Seraiah, ọmọ Neriah, ọmọ Maseiah, nígbà o ń lọ ni ti Sedekiah, ọba Juda, Babeli ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀. Seraiah yìí ìjòyè ibùdó. 60 Jeremiah kọ gbogbo ̀rọ̀ ibi yóò sórí Babeli sínú ìwé kan, àní gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí a kọ Babeli. 61 Jeremiah sọ fún Seraiah , "Nígbà ìwọ Babeli, ìwọ ó , ìwọ ó ka gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí. 62 ìwọ ó , Olúwa ìwọ ti sọ̀rọ̀ ibí , láti e kúrò, ẹnikẹ́ni ṣe gbé inú rẹ̀, àti ènìyàn àti ẹran, nítorí yóò di ahoro láéláé.63 51.63-64: If 18.21.Yóò ṣe, nígbà ìwọ parí kíka ìwé yìí tán ìwọ ó di òkúta mọ́ ọn, ó sọ ́ àárín odò Eufurate. 64 ìwọ , Báyìí Babeli yóò , yóò tún dìde kúrò nínú ibi èmi ó sórí rẹ̀: àárẹ̀ yóò wọn.’ "

Títí ìhín ni ̀rọ̀ Jeremiah.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também