Pular para o conteúdo
Publicidade

Jeremiah 47

Àṣọtẹ́lẹ̀ nípa àwọn ará Filistini

1 47.1-7: Isa 14.29-31; El 25.15-17; Am 1.6-8; Sf 2.4-7; Sk 9.5-7. Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì Jeremiah nípa àwọn Filistini, ó di Farao dojúkọ Gasa.

2 Báyìí ni Olúwa :

"Wo omi ti ń ru sókè àríwá,

wọn ó di odò ń bo bèbè mọ́lẹ̀.

Wọn borí ilẹ̀ àti ohun gbogbo lórí rẹ̀,

ìlú àti àwọn ń gbé nínú wọn.

Àwọn ènìyàn yóò kígbe,

gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà yóò hu

3 nígbà wọ́n gbọ́ ìró títẹ̀pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin alágbára

nígbà wọ́n gbọ́ ariwo kẹ̀kẹ́ ogun ̀ńlá

àti iye kẹ̀kẹ́ wọn.

Àwọn baba ran àwọn ọmọ lọ́wọ́;

ọwọ́ wọn yóò kákò.

4 Nítorí ọjọ́ náà ti

láti pa àwọn Filistini run,

a àwọn ó

ó ran Tire àti Sidoni lọ́wọ́ kúrò.

Olúwa ti ṣetán láti pa Filistini run,

àwọn ó agbègbè Kafitori.

5 Gasa yóò irun orí rẹ̀ nínú ̀fọ̀.

A ó pa Aṣkeloni lẹ́nu mọ́;

ìyókù pẹ̀tẹ́lẹ̀,

ìwọ yóò ti ara rẹ lọ́gbẹ́ pẹ́ ?

6 "̀yin kígbe, è, idà Olúwa,

yóò ti pẹ́ ìwọ yóò sinmi?

Padà sínú àkọ̀ rẹ;

sinmi o dákẹ́ jẹ́́.’

7 Ṣùgbọ́n báwo ni yóò ṣe sinmi,

nígbà Olúwa ti pàṣẹ fún un,

nígbà ó ti pa á láṣẹ

láti dojúkọ Aṣkeloni àti agbègbè rẹ̀."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também