Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 6

Àìronúpìwàdà Israẹli

1 ", jẹ́ a padà sọ́dọ̀ Olúwa

ó ti ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ

ṣùgbọ́n yóò wa láradá

Ó ti pa lára

ṣùgbọ́n yóò ojú ọgbẹ́ wa.

2 Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ

ọjọ́ kẹta yóò wa padà bọ̀ sípò

a ba à le gbé níwájú rẹ̀.

3 jẹ́ a mọ Olúwa;

jẹ́ a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ́n.

Gẹ́gẹ́ oòrùn ṣe ń yọ,

yóò jáde;

yóò tọ̀ òjò,

òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀."

4 "ni èmi ó ṣe pẹ̀rẹ, Efraimu?

ni èmi ó ṣe pẹ̀rẹ, Juda?

Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀

ìrì ìdájí ó kọjá lọ kíákíá.

5 Nítorí náà ni mo ṣe e yín wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì,

Mo pa yín pẹ̀̀rọ̀ ẹnu mi,

ìdájọ́ mi tàn i mọ̀nàmọ́lórí yín.

6 6.6: Mt 9.13; 12.7. Nítorí àánú ni mo fẹ́, í ṣe ẹbọ;

àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.

7 i Adamu, wọ́n da májẹ̀

wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ mi níbẹ̀.

8 Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú

ń ṣiṣẹ́ ̀ṣẹ̀, a ti fi ̀ṣẹ̀ á jẹ́.

9 adigunjalè ṣe ń ba bùba de àwọn ènìyàn

bẹ́̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀;

wọ́n ń pànìyàn lójú ̀lọ Ṣekemu,

wọ́n ń ̀ṣẹ̀ ó ti ni lójú.

10 Mo ti ohun ba ni lẹ́

ilé Israẹli.

Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè

Israẹli di aláìmọ́.

11 "Àti fún ìwọ, Juda,

a ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ.

"Nígbà mo fẹ́ ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também