Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 12

1 Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;

o ń lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀-oòrùn gbogbo ọjọ́.

O ń gbèrú nínú irọ́

o májẹ̀pẹ̀Asiria

o fi òróró olifi ránṣẹ́ Ejibiti.

2 Olúwa ẹjọ́ kan yóò Juda ,

yóò ìyà jẹ Jakọbu gẹ́gẹ́ ̀rẹ̀

yóò sán fún un gẹ́gẹ́ i ìṣe rẹ̀.

3 Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ ni gìgísẹ̀,

àti nípa ipá rẹ̀ ó ni agbára pẹ̀Ọlọ́run

4 Ó angẹli ja ìjàkadì, ó borí rẹ̀,

o sọkún, ó bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere rẹ̀.

Ó Olúwa Beteli,

Ó a sọ̀rọ̀ níbẹ̀,

5 àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;

Olúwa ni orúkọ ìrántí rẹ̀.

6 Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;

di ìfẹ́ àti ìdájọ́ òdodo

dúró de Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.

7 Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké

o fẹ́ràn láti rẹ́ ni jẹ.

8 12.8: If 3.17. Efraimu gbéraga,

"Èmi ìní fún ara mi, mo ti di ọlọ́rọ̀,

pẹ̀gbogbo ọrọ̀ mi yìí, wọn le àìṣedéédéé

tàbí ̀ṣẹ̀ kankan mọ́ mi lọ́wọ́."

9 "Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;

ẹni ó mu jáde láti ilẹ̀ Ejibiti;

èmi yóò tún yín gbé nínú àgọ́

i ọjọ́ àjọ̀dún a yàn wọ̀n-ọn-nì.

10 Mo sọ fún àwọn wòlíì,

mo fi ̀pọ̀lọpọ̀ ìran hàn wọ́n

mo pa òwe láti ẹnu wòlíì wọn."

11 Gileadi ha burú ?

Àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ́ asán.

Ǹjẹ́ wọ́n ń fi akọ màlúù ẹbọ Gilgali?

Gbogbo pẹpẹ wọ́n dàbí ebè

nínú aporo oko.

12 Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;

Israẹli sìn o fẹ́ ìyàwó

ó ṣe ìtọ́ẹran láti fi san owó ìyàwó.

13 Olúwa lo wòlíì kan láti Israẹli jáde láti Ejibiti,

nípasẹ̀ wòlíì kan ó ṣe ìtọ́rẹ̀.

14 Ṣùgbọ́n Efraimu ti un bínú gidigidi;

Olúwa rẹ̀ yóò fi ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ orí rẹ̀

òun yóò san án padà fún un nítorí ìwà ̀gàn an rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também