Pular para o conteúdo
Publicidade

Hosea 9

Ìdájọ́ fún ẹsẹ̀ Israẹli

1 ṣe yọ̀, ìwọ Israẹli;

ṣe ìhó ayọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè yòókù.

Nítorí ti jẹ́ aláìṣòótọ́ si Ọlọ́run yín.

fẹ́ràn láti gba owó iṣẹ́ àgbèrè

gbogbo ilẹ̀ ìpakà.

2 Àwọn ilẹ̀ ìpakà àti ilé ìfun wáìnì fún àwọn ènìyàn lóúnjẹ

wáìnì tuntun yóò tàn láìròtẹ́lẹ̀.

3 Wọn ṣẹ́ilé Olúwa

Efraimu yóò padà Ejibiti,

yóò jẹ oúnjẹ àìmọ́ Asiria.

4 Wọn fi ọrẹ ohun mímu fún Olúwa.

Bẹ́̀ ni ìrúbọ wọn , inú rẹ̀ dùn.

Ìrú ẹbọ bẹ́̀ yóò dàbí oúnjẹ àwọn ń ṣọ̀fọ̀.

Gbogbo àwọn jẹ ́ yóò di aláìmọ́.

Oúnjẹ yìí yóò fún wọn fúnra wọn

orí tẹmpili Olúwa.

5 ni ̀yin ó ṣe ọjọ́ àjọ̀dún a yàn

àwọn ọjọ́ àjọ̀dún Olúwa?

6 wọ́n tilẹ̀ yọ́ kúrò lọ́wọ́ ìparun

Ejibiti yóò wọn jọ,

Memfisi yóò sin wọ́n.

Ibi ìsọjọ̀ fàdákà wọn ni ̀gún yóò jogún,

̀gún yóò bo àpótí ìṣúra fàdákà wọn.

̀gún yóò bo

gbogbo àgọ́ wọn.

7 9.7: Lk 21.22. Àwọn ọjọ́ ìjìyà ń bọ̀;

àwọn ọjọ́ ìṣirò iṣẹ́ ti .

Jẹ́ Israẹli mọ èyí.

Nítorí ̀ṣẹ̀ yín pọ̀

ìkórìíra yín pọ̀ gan an ni.

A ka àwọn wòlíì òmùgọ̀,

a ka ẹni ìmísí asínwín.

8 Wòlíì, papọ̀ pẹ̀Ọlọ́run,

ni olùṣọ́ Efraimu.

Síbẹ̀ ìdẹ̀kùn dúró é gbogbo ̀rẹ̀

àti ìkórìíra ilé Ọlọ́run rẹ̀.

9 Wọ́n ti gbilẹ̀ nínú ìwà ìbàjẹ́

gẹ́gẹ́ i ọjọ́ Gibeah

Ọlọ́run yóò rántí ìwà búburú wọn

yóò jẹ wọ́n fún ̀ṣẹ̀ wọn.

10 "Mo Israẹli èso àjàrà aginjù.

Mo àwọn baba yín,

àkọ́pọ́n nínú igi ̀pọ̀tọ́ àkọ́so rẹ̀.

Ṣùgbọ́n wọ́n tọ Baali-Peori lọ,

wọ́n wọn sọ́tọ̀ fún òrìṣà ń ìtìjú ni,

ohun ìríra wọn gẹ́gẹ́ wọn ti fẹ́. 11 Ògo Efraimu yóò lọ ẹyẹ

ìfẹ́rakù, ìlóyún àti ìbímọ.

12 wọ́n tilẹ̀ tọ́ ọmọ dàgbà.

Èmi yóò wọn ṣọ̀fọ̀ lórí gbogbo wọn.

Ègbé ni fún wọn,

nígbà mo yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn!

13 Mo Efraimu ìlú Tire

a tẹ̀ibi dáradára

ṣùgbọ́n Efraimu yóò àwọn

ọmọ rẹ̀ jáde fún àwọn apànìyàn."

14 Fún wọn, Olúwa!

ni ìwọ yóò fún wọn?

Fún wọn inú ń ba oyún jẹ́

àti ọyàn gbígbẹ.

15 "Nítorí gbogbo ìwà búburú wọ́n Gilgali,

Mo kórìíra wọn níbẹ̀,

nítorí ìwà ̀ṣẹ̀ wọn.

Èmi yóò wọn jáde ilé mi,

Èmi ìfẹ́ wọn mọ́

ọlọ̀tẹ̀ ni gbogbo olórí wọn.

16 Efraimu ti rẹ̀ dànù

gbogbo rẹ̀ ti rọ,

so èso.

wọ́n tilẹ̀ bímọ.

Èmi ó pa àwọn ọmọ wọn wọ́n fẹ́ràn jùlọ."

17 Ọlọ́run mi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀

nítorí wọn gbọ́rọ̀ i;

wọn yóò di alárìnkiri láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também