Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 19

Ọmọ Lefi kan àti àlè rẹ̀

1 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì Israẹli ọba.

̀kan nínú àwọn ọmọ Lefi ń gbé ibi ó pamọ́ nínú àwọn agbègbè òkè Efraimu, àlè kan láti Bẹtilẹhẹmu Juda. 2 Ṣùgbọ́n àlè rẹ̀ náà ṣe panṣágà i, òun fi sílẹ̀, ó padà lọ ilé baba rẹ̀ Bẹtilẹhẹmu ti Juda, ó ibẹ̀ ìwọ̀n oṣù mẹ́rin, 3 ọkọ rẹ̀ lọ ibẹ̀ láti rọ̀ ́ ó padà ̀dọ̀ òun. Nígbà ó ń lọ ó ìránṣẹ́ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì lọ́wọ́, obìnrin náà un wọ inú ilé baba rẹ̀ lọ, nígbà baba obìnrin náà i ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á. 4 Àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà rọ̀ ́, ó borí rẹ̀ láti a dúró fún ìgbà díẹ̀, òun dúró fún ọjọ́ mẹ́ta, ó ń jẹ, ó ń mu, ó ń sùn níbẹ̀.

5 ọjọ́ kẹrin, wọ́n dìde òwúrọ̀ kùtùkùtù òun múra láti padà lọ, ṣùgbọ́n baba ọmọbìnrin náà fún àna rẹ̀ , "Fi ohun jíjẹ díẹ̀ gbé inú nígbà náà ìwọ máa lọ." 6 Àwọn méjèèjì jùmọ̀ jókòó láti jọ jẹun àti láti jọ mu. Lẹ́yìn èyí ni baba ọmọbìnrin , "Jọ̀wọ́ dúró alẹ́ yìí o gbádùn ara rẹ." 7 Nígbà ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, baba ìyàwó rẹ̀ rọ̀ ́, torí náà ó sùn níbẹ̀ alẹ́ ọjọ́ náà. 8 òwúrọ̀ ọjọ́ karùn-ún nígbà ó dìde láti lọ, baba ọmọbìnrin , "Fi oúnjẹ gbé ara . Dúró de ̀sán!" Àwọn méjèèjì jùmọ̀ jọ jẹun.

9 Nígbà ọkùnrin náà, pẹ̀àlè àti ìránṣẹ́ rẹ̀, dìde láti máa lọ, àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà , "ó ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, dúró níbí, ọjọ́ ti lọ. Dúró o gbádùn ara rẹ. Ìwọ àárọ̀ kùtùkùtù ̀la ìwọ máa lọ ilé." 10 Ṣùgbọ́n nítorí òun fẹ́ dúró mọ́ níbẹ̀ òru náà ọkùnrin náà kúrò ó gba ̀Jebusi: ̀Jerusalẹmu pẹ̀àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ méjèèjì ó fi í gàárì àti àlè rẹ̀.

11 Nígbà wọ́n súnmọ́ Jebusi ilẹ̀ ti fẹ́ ṣú tan, ìránṣẹ́ náà sọ fún ̀rẹ̀ , ", jẹ́ a dúró ìlú yìí í ṣe ti àwọn ará Jebusi a sùn níbẹ̀."

12 ̀rẹ̀ a lóhùn , "Rárá o, àwa yóò wọ ìlú àwọn àjèjì, àwọn olùgbé ibẹ̀ í ṣe ọmọ Israẹli, a yóò Gibeah." 13 Ó fi kún un , jẹ́ a gbìyànjú a Gibeah tàbí Rama a sùn ̀kan nínú wọn. 14 Wọ́n tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn, oòrùn wọ̀ wọ́n ti súnmọ́ Gibeah ṣe ti àwọn Benjamini. 15 Wọ́n yípadà wọ́n lọ inú ìlú Gibeah láti wọ̀ síbẹ̀ òru náà, wọ́n lọ wọ́n jókòó níbi gbọ̀ngàn ìlú náà, ṣùgbọ́n ẹni ó gbà wọ́n sínú ilé rẹ̀ láti wọ̀ .

16 alẹ́ ọjọ́ náà ọkùnrin arúgbó kan láti àwọn òkè Efraimu, ṣùgbọ́n ń gbé Gibeah (ibẹ̀ ni àwọn ̀Benjamini ń gbé) ń ti ibi iṣẹ́ rẹ̀ bọ̀ láti inú oko. 17 Nígbà ó wòkè ó arìnrìn-àjò náà gbọ̀ngàn ìlú náà, ọkùnrin arúgbó yìí bi í léèrè , "Níbo ni ò ń lọ? Níbo ni o ti ń bọ̀?"

18 Ọmọ Lefi náà a lóhùn , "Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni àwa ti ń bọ̀, àwa ń lọ agbègbè ó pamọ́ àwọn òkè Efraimu níbi ti mo ń gbé. Mo ti lọ Bẹtilẹhẹmu ti Juda, èmi ń lọ ilé Olúwa nísinsin yìí. ẹni ó gbà ilé rẹ̀. 19 Àwa koríko àti oúnjẹ fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa àti oúnjẹ àti wáìnì fún àwa ìránṣẹ́ rẹèmi, ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti ̀dọ́mọkùnrin ó pẹ̀wa. A ò ṣe aláìní ohun kankan."

20 Ọkùnrin arúgbó náà . "Àlàáfíà fún , ó ti ó , èmi yóò pèsè gbogbo ohun o nílò, kìkì ìwọ ṣe sun ìgboro." 21 Òun wa ilé rẹ̀, ó ń bọ́ àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀. Lẹ́yìn ìgbà wọ́n ti wẹ ẹsẹ̀ wọn, àwọn àlejò náà jẹ, wọ́n mu.

22 Ǹjẹ́ wọ́n ti ń ṣe àríyá, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin ìlú náà, àwọn ọmọ Beliali kan, ilé náà , wọ́n ń lu ìlẹ̀kùn; wọ́n sọ fún baálé ilé náà ọkùnrin arúgbó náà , "ọkùnrin ó wọ̀ sínú ilé rẹ , àwa mọ̀ ́n."

23 Ọkùnrin, baálé ilé náà jáde tọ̀ wọ́n lọ, ó fún un , "Bẹ́̀ kọ́ ̀yin arákùnrin mi, èmi bẹ̀ yín, ṣe hùwà búburú; nítorí ọkùnrin yìí ti wọ ilé mi, ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí. 24 Kíyèsi i, ọmọbìnrin mi ni èyí, wúńdíá, àti àlè rẹ̀; àwọn ni èmi ó jáde nísinsin yìí, ̀yin tẹ̀ wọ́n lógo, ̀yin ṣe wọn ó ti tọ́ lójú yín: ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí ni ̀yin ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí ."

25 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà fetí tirẹ̀. Nítorí náà ọkùnrin náà àlè rẹ̀ ó tari rẹ̀ jáde wọn, wọ́n a fi ipá lòpọ̀, wọ́n fi gbogbo òru náà a lòpọ̀, nígbà ó di àfẹ̀mọ́júmọ́ wọ́n jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́. 26 Nígbà ojúmọ́ bẹ̀rẹ̀ obìnrin náà padà lọ ilé ̀rẹ̀ , ó ṣubú lulẹ̀ lọ́, ó níbẹ̀ títí ó fi di òwúrọ̀.

27 Nígbà ̀rẹ̀ ó dìde òwúrọ̀ ó ṣí ìlẹ̀kùn ilé náà, ó bọ́ òde láti tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò rẹ̀, kíyèsi i àlè rẹ̀ ṣíṣubú iwájú ilé, ọwọ́ rẹ̀ di òpó ẹnu-ọ̀ibẹ̀ , 28 òun fún obìnrin náà , "Dìde jẹ́ a máa ̀wa lọ." Ṣùgbọ́n òun a lóhùn. Nígbà náà ni ọkùnrin náà gbé e orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó kọjá lọ ilé e rẹ̀.

29 Nígbà ó ilé, ó ̀bẹ ó àlè rẹ̀ oríkeríke ̀méjìlá, ó fi wọ́n ránṣẹ́ gbogbo agbègbè Israẹli. 30 Gbogbo ẹni ó i , "A ti i, bẹ́̀ a ì ṣe irú nǹkan yìí , í ṣe láti ọjọ́ Israẹli ti jáde Ejibiti títí di òní olónìí. ó , gbìmọ̀ràn, sọ fún wa ohun a yóò ṣe!"

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também