Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 1

Orílẹ̀-èdè Israẹli àwọn ará Kenaani tókù jagun

1 Lẹ́yìn ikú Joṣua, ni orílẹ̀-èdè Israẹli béèrè lọ́wọ́ Olúwa , "Èwo nínú ̀wa ni yóò kọ́kọ́ gòkè lọ àwọn ará Kenaani jagun fún wa?"

2 Olúwa dáhùn , "Juda ni yóò lọ; nítorí èmi ti fi ilẹ̀ náà e lọ́wọ́."

3 Nígbà náà ni àwọn olórí ̀Juda béèrè ìrànlọ́wọ́ láti ̀dọ̀ àwọn ọmọ Simeoni arákùnrin wọn , "wa gòkè lọ ilẹ̀ a ti fi fún wa, láti àwọn ará Kenaani a wọn kúrò, àwa pẹ̀yóò a yín lọ ilẹ̀ tiyín bákan náà láti ràn yín lọ́wọ́." Àwọn ọmọ-ogun Simeoni àwọn ọmọ-ogun Juda lọ.

4 Nígbà àwọn ọmọ-ogun Juda kọlu wọ́n, Olúwa fi àwọn ará Kenaani àti àwọn ará Peresi wọn lọ́wọ́, wọ́n pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ọkùnrin Beseki. 5 Beseki ni wọ́n ti Adoni-Beseki, wọ́n a jagun, wọ́n ṣẹ́gun àwọn ará Kenaani àti Peresi. 6 Ọba Adoni-Beseki àsálà, ṣùgbọ́n ogun Israẹli lépa rẹ̀ wọ́n a, wọ́n àwọn àtàǹpàkò ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀.

7 Nígbà náà ni Adoni-Beseki , "Àádọ́rin ọba ni èmi ti àtàǹpàkò wọn wọ́n ń ṣa èérún oúnjẹ jẹ lábẹ́ tábìlì mi. Báyìí Ọlọ́run ti san án fún mi gẹ́gẹ́ ohun mo ṣe wọn." Wọ́n un Jerusalẹmu, ó síbẹ̀.

8 Àwọn ológun Juda ṣẹ́gun Jerusalẹmu, wọ́n o, wọ́n fi ojú idà kọlù ú, wọ́n dáná sun ìlú náà.

9 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ogun Juda sọ̀kalẹ̀ lọ láti àwọn ará Kenaani ń gbé àwọn ìlú orí òkè gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀ òkè lápá ìwọ̀-oòrùn Juda jagun. 10 1.10: Jo 15.13-19.1.10-15: Jo 15.14-19.Ogun Juda tún ṣígun tọ ará Kenaani ń gbé Hebroni (orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Kiriati-Arba) ó ṣẹ́gun Ṣeṣai, Ahimani àti Talmai. 11 Láti ibẹ̀, wọ́n wọ́de ogun láti ibẹ̀ lọ àwọn ènìyàn ń gbé Debiri (à ń Kiriati-Seferi nígbà kan ).

12 Kalebu , "Èmi yóò fi ọmọbìnrin mi Aksa fún ọkùnrin ó kọlu Kiriati-Seferi, ó gbà á ìgbéyàwó." 13 Otnieli ọmọ Kenasi, àbúrò Kalebu gbà á, báyìí ni Kalebu fi ọmọbìnrin rẹ̀ Aksa fún un ìyàwó.

14 ọjọ́ kan, nígbà Aksa lọ ̀dọ̀ Otnieli, ó rọ̀ ́ ó béèrè ilẹ̀ oko lọ́wọ́ baba rẹ̀. Nígbà náà ni Aksa sọ̀kalẹ̀ orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, Kalebu béèrè , "ni èmi ṣe fún ?"

15 Aksa dáhùn , "Mo ń fẹ́ o ṣe ojúrere kan fún mi, nígbà ti o ti fún mi ilẹ̀ gúúsù, fún mi ìsun omi náà pẹ̀." Kalebu fún un ìsun òkè àti ìsun ìsàlẹ̀.

16 Àwọn ìran Keni wọ́n jẹ́ àna Mose àwọn ọmọ Juda gòkè láti ìlú ̀pẹ lọ aginjù Juda gúúsù Aradi; wọ́n lọ, orílẹ̀-èdè méjèèjì jùmọ̀ ń gbé pọ̀ láti ìgbà náà.

17 Ó ṣe, àwọn ológun Juda tẹ̀àwọn ológun Simeoni arákùnrin wọn, wọ́n lọ àwọn ará Kenaani ń gbé Sefati jagun, wọ́n run ìlú náà pátápátá, báyìí àwa yóò pe ìlú náà Horma (Horma èyí ń jẹ́ ìparun). 18 Àwọn ogun Juda ṣẹ́gun Gasa àti àwọn agbègbè rẹ̀, Aṣkeloni àti Ekroni pẹ̀àwọn ìlú ó ̀kọ̀̀kan wọn .

19 Olúwa pẹ̀̀Juda, wọ́n gba ilẹ̀ òkè, ṣùgbọ́n wọn le àwọn ènìyàn ó pẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí wọ́n kẹ̀kẹ́ ogun onírin. 20 Gẹ́gẹ́ Mose ti ṣèlérí, wọ́n fún Kalebu Hebroni, ó àwọn ń gbé ibẹ̀ kúrò; àwọn náà ni ìran àwọn ọmọ Anaki mẹ́ta. 21 Àwọn ̀Benjamini ni wọn le àwọn Jebusi wọ́n ń gbé Jerusalẹmu, nítorí náà wọ́n ń gbé àárín àwọn Israẹli títí di òní.

22 Àwọn ̀Josẹfu Beteli jagun, Olúwa síwájú pẹ̀wọn. 23 Nígbà ̀Josẹfu rán àwọn ènìyàn láti lọ yọ́ Beteli (orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ ni Lusi). 24 Àwọn ayọ́lẹ̀náà ọkùnrin kan ń jáde láti inú ìlú náà , wọ́n fún un , "Fi ̀àtiwọ ìlú yìí hàn , àwa ó ̀rẹ , a ó ṣe àánú fún ." 25 Ó fi ̀ìlú náà hàn wọ́n, wọ́n fi ojú idà kọlu ìlú náà, ṣùgbọ́n wọ́n ọkùnrin náà àti gbogbo ìdílé rẹ̀ si. 26 Ọkùnrin náà lọ ilẹ̀ àwọn ará Hiti, ó tẹ ìlú kan , ó pe orúkọ rẹ̀ Lusi, èyí ni orúkọ rẹ̀ títí di òní.

27 1.27,28: Jo 17.11-13. Ṣùgbọ́n Manase àwọn ará Beti-Ṣeani àti ìlú rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì jáde, tàbí àwọn ará Taanaki àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Dori àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Ibleamu àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Megido àti àwọn ìgbèríko ó i , torí àwọn ará Kenaani ti pinnu láti máa gbé ìlú náà. 28 Nígbà àwọn ọmọ Israẹli di alágbára, wọ́n àwọn ará Kenaani sìn i ẹrú, ṣùgbọ́n wọn fi agbára wọn jáde kúrò ilẹ̀ náà. 29 1.29: Jo 16.10.Efraimu náà àwọn ará Kenaani ó ń gbé Geseri jáde, ṣùgbọ́n àwọn ará Kenaani ń gbé láàrín àwọn ̀Efraimu. 30 Bẹ́̀ ni àwọn Sebuluni àwọn ará Kenaani ń gbé Kitironi jáde tàbí àwọn ará Nahalali, ṣùgbọ́n wọ́n sọ wọ́n di ẹrú. Wọ́n ń sin àwọn ará Sebuluni. 31 Bẹ́̀ ni Aṣeri àwọn ń gbé Akko tàbí Sidoni tàbí Ahlabu tàbí Aksibu tàbí Helba tàbí Afiki tàbí Rehobu. 32 Ṣùgbọ́n nítorí àwọn ará Aṣeri ń gbé láàrín àwọn ará Kenaani wọ́n ni ilẹ̀ náà. 33 Àwọn ̀Naftali pẹ̀àwọn ará Beti-Ṣemeṣi àti Beti-Anati jáde; ṣùgbọ́n àwọn ̀Naftali náà ń gbé àárín àwọn ará Kenaani ó ti ilẹ̀ náà , ṣùgbọ́n àwọn ń gbé Beti-Ṣemeṣi àti Beti-Anati ń sìn ìsìn tipátipá. 34 Àwọn ará Amori fi agbára àwọn ̀Dani dúró àwọn ìlú orí òkè, wọn jẹ́ wọn sọ̀kalẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀. 35 Àwọn ará Amori ti pinnu láti dúró lórí òkè Heresi àti òkè Aijaloni àti ti Ṣaalbimu, ṣùgbọ́n nígbà ̀Josẹfu di alágbára wọ́n borí Amori wọ́n wọn sìn. 36 Ààlà àwọn ará Amori bẹ̀rẹ̀ láti ìgòkè Akrabbimu kọjá lọ Sela àti síwájú i.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também