Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 15

̀san Samsoni lára àwọn ará Filistini

1 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, àkókò ìkórè alikama, Samsoni ̀dọ́ ewúrẹ́ kan láti bẹ ìyàwó rẹ̀ . Ó , "Èmi yóò wọ yàrá ìyàwó mi lọ." Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ gbà á láààyè láti wọlé.

2 Baba ìyàwó a lóhùn , "Ó mi lójú o kórìíra rẹ̀, torí náà mo ti fi fún ̀rẹ́ rẹ, ṣe àbúrò rẹ̀ obìnrin ha lẹ́jùlọ? Fẹ́ dípò rẹ̀."

3 Samsoni dáhùn , "àkókò yìí mo ṣe àwọn Filistini ibi èmi yóò jẹ́ aláìjẹ̀bi." 4 Samsoni jáde lọ, ó ̀́dúnrún (300) kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ó so ìrù wọn mọ́ ara wọn méjì méjì. Ó ètùfù iná, ó so ó mọ́ àwọn ìrù ó so pọ̀. 5 Ó fi iná ran àwọn ètùfù ó so náà, ó jọ̀wọ́ wọn lọ́wọ́ lọ sínú àwọn oko ọkà àwọn Filistini. Ó àwọn pòpóòrò ọkà ó dúró àti àwọn a ìtí, ìtí, pẹ̀àwọn ọgbà àjàrà àti olifi.

6 Nígbà àwọn Filistini béèrè , "Ta ni ó ṣe èyí?" Wọ́n wọn lóhùn , "Samsoni ará Timna ni, nítorí a gba ìyàwó rẹ̀ fún ̀rẹ́ rẹ̀."

Nítorí náà àwọn Filistini lọ wọ́n sun obìnrin náà àti baba rẹ̀. 7 Samsoni sọ fún un , "Nítorí ̀yin ṣe èyí, èmi ó gbẹ̀san lára yín, lẹ́yìn náà èmi yóò dẹ́kun." 8 Ó kọlù wọ́n pẹ̀ìbínú àti agbára ńlá, ó pa ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wọn. Lẹ́yìn náà ni ó lọ, ó dúró nínú ihò àpáta kan nínú àpáta Etamu.

9 Àwọn ará Filistini dìde ogun Juda, wọ́n ti tan ara wọn agbègbè Lehi. 10 Àwọn ọkùnrin Juda béèrè , "Èéṣe fi gbóguntì ?"

Ìdáhùn wọn ni , "A láti Samsoni ìgbèkùn, a ṣe i òun ti ṣe wa."

11 Nígbà náà ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) ọkùnrin láti Juda sọ̀kalẹ̀ lọ ihò àpáta nínú àpáta Etamu, wọ́n sọ fún Samsoni , "ti àwọn Filistini ń ṣe alákòóso lórí wa? ni o ṣe wa?"

Òun dáhùn , "Ohun wọ́n ṣe mi ni èmi náà ṣe wọn."

12 Wọ́n , "Àwa láti ́, a fi ́ àwọn Filistini lọ́wọ́."

Samsoni , "búra fún mi , ̀yin yóò fúnra yín pa ."

13 "Àwa gbà," ni ìdáhùn wọn. "Àwa yóò kàn ́, àwa yóò fi ́ wọn lọ́wọ́, àwa yóò pa ́." Wọ́n pẹ̀okùn tuntun méjì, wọ́n u jáde láti ihò àpáta náà. 14 ó ti súnmọ́ Lehi, àwọn Filistini ń pariwo wọ́n ṣe ń bọ̀. ̀Olúwa e pẹ̀agbára. Àwọn okùn ọwọ́ rẹ̀ dàbí òwú ó jóná, ìdè ọwọ́ rẹ̀ kúrò ọwọ́ rẹ̀. 15 Nígbà ó egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tuntun kan, ó un, ó fi pa ẹgbẹ̀rún (1,000) ọkùnrin.

16 Samsoni ,

"Pẹ̀egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan,

mo sọ wọ́n di òkìtì kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.

Pẹ̀egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan,

mo ti pa ẹgbẹ̀rún (1,000) ọkùnrin."

17 Nígbà ó dákẹ́ ̀rọ̀ í sọ, ó ju egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ náà , wọ́n pe ibẹ̀ Ramati-Lehi (ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ pa).

18 Nítorí òǹgbẹ gbẹ ́ gidigidi, ó pe Olúwa, , "Ìwọ ti fún ìránṣẹ́ ìṣẹ́gun ó tóbi yìí. Ṣé èmi yóò ha pẹ̀òǹgbẹ, èmi ṣubú ọwọ́ àwọn aláìkọlà ènìyàn?" 19 Nígbà náà ni Ọlọ́run la kòtò ìsun omi ó Lehi, omi jáde láti inú rẹ̀. Nígbà Samsoni mi tan, agbára rẹ̀ padà, ọkàn sọjí, fún ìdí èyí wọ́n pe ìsun omi náà ni. Ẹni Hakkore (orísun ẹni ó pe Ọlọ́run) èyí ó Lehi di òní.

20 Samsoni ṣe ìdájọ́ Israẹli fún ogún ọdún àkókò àwọn ará Filistini.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também