Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 21

Àwọn aya fún àwọn ̀Benjamini

1 Àwọn ọkùnrin Israẹli ti búra Mispa , "ẹnìkan nínú wa yóò fi ọmọ obìnrin rẹ̀ fún ̀Benjamini ìyàwó."

2 Àwọn ènìyàn náà lọ Beteli: ilé Ọlọ́run, níbi wọ́n jókòó níwájú Ọlọ́run títí di àṣálẹ́, wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sọkún kíkorò. 3 Wọ́n sọkún , "Háà! Olúwa Ọlọ́run Israẹli, èéṣe nǹkan yìí fi ṣẹlẹ̀ Israẹli? Èéṣe ̀kan yóò fi run nínú Israẹli lónìí?"

4 òwúrọ̀ ọjọ́ kejì àwọn ènìyàn náà mọ pẹpẹ kan wọ́n ẹbọ sísun àti ọrẹ àlàáfíà.

5 Àwọn ọmọ Israẹli béèrè , "Èwo nínú ̀Israẹli ni ó kọ̀ láti péjọ síwájú Olúwa?" Torí wọ́n ti fi ìbúra ńlá búra , ẹnikẹ́ni ó kọ̀ láti péjọ níwájú Olúwa Mispa pípa ni àwọn yóò pa á.

6 Àwọn ọmọ Israẹli banújẹ́ fún àwọn arákùnrin wọn, àwọn ̀Benjamini. Wọ́n , "A ti ̀kan kúrò lára Israẹli lónìí." 7 Báwo ni a yóò ṣe aya fún àwọn ó ṣẹ́, nítorí àwa ti fi Olúwa búra láti fi ̀kankan nínú àwọn ọmọbìnrin wa fún wọn aya. 8 Wọ́n béèrè , "Èwo ni nínú ̀Israẹli ni ó kọ̀ láti àwọn ènìyàn péjọ níwájú Olúwa Mispa?" Wọ́n i ẹnikẹ́ni ó wa láti Jabesi Gileadi ó ibùdó fún àjọ náà. 9 Nítorí nígbà wọ́n ka àwọn ènìyàn, wọ́n i ẹnìkankan láti inú àwọn ará Jabesi Gileadi ó níbẹ̀.

10 Àwọn ìjọ ènìyàn náà rán ẹgbàá mẹ́(12,000) àwọn jagunjagun ọkùnrin, lọ Jabesi Gileadi wọ́n fún wọn àṣẹ , lọ fi idà kọlu gbogbo àwọn ó níbẹ̀, pẹ̀àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ wẹ́wẹ́. 11 Wọ́n , "Èyí ni ̀yin yóò ṣe, pa gbogbo ọkùnrin àti gbogbo obìnrin í ṣe wúńdíá." 12 Wọ́n àwọn irinwó (400) ̀dọ́bìnrin mọ ọkùnrin nínú àwọn olùgbé Jabesi Gileadi, wọ́n wọn lọ ibùdó Ṣilo àwọn ará Kenaani.

13 Gbogbo ìjọ àwọn ènìyàn ránṣẹ́ àlàáfíà àwọn Benjamini ihò àpáta Rimoni. 14 Àwọn ̀Benjamini náà padà àkókò náà, wọ́n fún wọn àwọn obìnrin Jabesi Gileadi. Ṣùgbọ́n wọn kárí gbogbo wọn.

15 Àwọn ènìyàn náà káàánú nítorí ̀Benjamini, nítorí Olúwa fi àlàfo kan sílẹ̀ nínú àwọn ̀Israẹli. 16 Àwọn olórí ìjọ àwọn ènìyàn náà , "ni àwa yóò ṣe láti aya fún àwọn ọkùnrin ó nígbà a ti pa gbogbo àwọn obìnrin Benjamini run?" 17 Wọ́n , "Àwọn ó ṣẹ́wọ́n nínú àwọn ̀Benjamini láti ogún àti àrólé, ̀kan nínú Israẹli ṣe di píparun kúrò orí ilẹ̀. 18 Àwa le fi àwọn ọmọbìnrin wa fún wọn aya, nítorí àwa ọmọ Israẹli ti ṣe ìbúra yìí , Ègún ni fún ẹnikẹ́ni ó fi aya fún ẹnikẹ́ni nínú ̀Benjamini.’ " 19 Wọ́n , "Kíyèsi i ayẹyẹ ọlọ́dọọdún fún Olúwa Ṣilo ìhà àríwá Beteli àti ìhà ìlà-oòrùn òpópó náà ó gba Beteli kọjá Ṣekemu, àti ìhà gúúsù Lebona."

20 Wọ́n fi àṣẹ fún àwọn ará Benjamini , "lọ fi ara pamọ́ nínú àwọn ọgbà àjàrà 21 ìmúrasílẹ̀. Nígbà àwọn ọmọbìnrin Ṣilo jáde láti lọ darapọ̀ fún ijó, yára jáde láti inú àwọn ọgbà àjàrà wọ̀n-ọn-nì ẹnìkọ̀̀kan yín gbé aya kan nínú àwọn ọmọbìnrin Ṣilo padà ilẹ̀ Benjamini. 22 Nígbà àwọn baba wọn tàbí àwọn arákùnrin wọn fi ẹjọ́ sùn , àwa yóò fún wọn , ṣe oore nípa ríràn wọ́n lọ́wọ́, nítorí àwa aya fún wọn àkókò ogun, ̀yin jẹ̀bi, nítorí ̀yin kọ́ ni ó fi àwọn ọmọbìnrin yín fún wọn aya.’ "

23 Èyí ni ohun àwọn ̀Benjamini ṣe. Nígbà àwọn ọmọbìnrin náà ń lọ́wọ́, ọkùnrin kọ̀̀kan ọmọbìnrin kọ̀̀kan, wọ́n gbé e lọ láti di aya rẹ̀. Wọ́n padà ilẹ̀ ìní wọn, wọ́n tún àwọn ìlú náà kọ́, wọ́n tẹ̀sínú wọn.

24 àkókò náà, àwọn ọmọ Israẹli kúrò ibẹ̀, wọ́n lọ ilé àti ̀rẹ̀ olúkúlùkù ilẹ̀ ìní rẹ̀.

25 àwọn ọjọ́ wọ̀nyí, ọba ilẹ̀ Israẹli; olúkúlùkù ń ṣe ó ti tọ́ ojú ara rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também