Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 21

Manase ọba Juda

1 21.1-9: 2Ki 33.1-9. Manase jẹ́ ẹni ọdún méjìlá nígbà ó bẹ̀rẹ̀ ìjọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún márùndínlọ́gọ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Hẹfisiba. 2 Ó ṣe búburú ojú Olúwa, ó tẹ̀iṣẹ́ ìríra àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli. 3 Ó tún ibi gíga baba rẹ̀ Hesekiah ó parun kọ́. Ó tún gbé pẹpẹ Baali dìde, ó ṣe ère òrìṣà Aṣerah, gẹ́gẹ́ Ahabu ọba Israẹli ti ṣe. Ó tẹríba gbogbo ogun ̀run, ó ń sìn wọ́n. 4 Ó kọ́ pẹpẹ nínú ilé a kọ́ fún Olúwa, èyí Olúwa ti sọ , "Jerusalẹmu ni èmi yóò kọ orúkọ mi ." 5 àgbàlá méjèèjì ilé Olúwa, ó kọ́ pẹpẹ fún gbogbo àwọn ìrúbọ nínú ilé, ṣe iṣẹ́ àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó béèrè lọ́wọ́ àwọn òkú àti àwọn oṣó. Ó ṣe ̀pọ̀ búburú ojú Olúwa, ó un bínú. 6 Ó fi àwọn ọmọ ara rẹ̀ ẹbọ nínú iná, ó ń ṣe àkíyèsí àfọ̀ṣẹ, ó ń lo àlúpàyídà, ó ń àwọn òku àti oṣó . Ó ṣe ̀pọ̀ ohun búburú ojú Olúwa láti un bínú.

7 Ó gbé ère fínfín òrìṣà Aṣerah ó ti ṣe, ó gbé e sínú ilé Olúwa, èyí Olúwa ti sọ fún Dafidi àti ọmọ rẹ̀ Solomoni, "Nínú ilé Olúwa yìí àti Jerusalẹmu, èmi ti yàn jáde lára gbogbo ̀Israẹli, èmi yóò kọ orúkọ mi títí láéláé. 8 Èmi jẹ́ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli yẹ̀ kúrò láti ilẹ̀ èmi fi fún àwọn baba ńlá wọn ó jẹ́ wọn yóò ṣe àkíyèsí láti ṣe gbogbo ohun èmi ti paláṣẹ fún wọn wọn pa gbogbo òfin ìránṣẹ́ mi Mose fi fún wọn mọ́." 9 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà tẹ́. Manase tàn wọ́n síwájú, bẹ́̀ ni wọ́n ṣe búburú ju gbogbo orílẹ̀-èdè Olúwa parun níwájú àwọn ọmọ Israẹli lọ.

10 Olúwa nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ wòlíì , 11 "Manase ọba Juda ti ṣe ̀ṣẹ̀ ohun ìríra. Ó ti ṣe ohun búburú jùlọ ju àwọn ará Amori lọ ẹni ó ti ṣáájú rẹ̀ ó ti ṣáájú Juda sínú ̀ṣẹ̀ pẹ̀àwọn ère rẹ̀. 12 Nítorí náà èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli, , Èmi le è lọ irú ibi báyìí sórí Jerusalẹmu àti Juda gbogbo etí olúkúlùkù ó gbọ́ nípa rẹ̀ le è . 13 Èmi yóò okùn ìwọ̀n kan a lórí Jerusalẹmu àti lórí Samaria àti òjé ìdiwọ̀n ti a lórí ilé Ahabu. Èmi yóò nu Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ ọkàn ń nu àwokòtò o ń un o ń dorí rẹ̀ kodò. 14 Èmi yóò kọ ìyókù àwọn ìní mi sílẹ̀ èmi yóò wọn àwọn ̀wọn lọ́wọ́. Wọn yóò di ìkógun àti ìjẹ fún gbogbo àwọn ̀wọn, 15 nítorí wọ́n ti ṣe búburú ojú mi, wọ́n ti mi bínú láti ọjọ́ baba ńlá wọn ti jáde láti Ejibiti títí di òní yìí."

16 Pẹ̀lúpẹ̀, Manase pẹ̀ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀ púpọ̀ ó kún Jerusalẹmu láti ìkangun ìkangun ̀gbẹ́ ̀ṣẹ̀ ó ti Juda ṣẹ̀, bẹ́̀ ni, wọ́n ṣe ohun búburú ojú Olúwa.

17 ti iṣẹ́ ìyókù ti ìjọba Manase, àti gbogbo ohun ó ṣe, àti fún ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀, ṣé wọ́n kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn àwọn ọba Juda? 18 21.18: 2Ki 33.20.Manase sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀ wọ́n sin ín nínú ọgbà ààfin rẹ̀, ọgbà Ussa. Amoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Amoni ọba Juda

19 21.19-24: 2Ki 33.21-25. Amoni jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà ó jẹ ọba. Orúkọ màmá rẹ̀ a máa jẹ́ Meṣulemeti ọmọbìnrin Harusi: ó láti Jotba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún méjì. 20 Ó ṣe búburú ojú Olúwa àti gẹ́gẹ́ baba rẹ̀ Manase ti ṣe. 21 Ó rìn gbogbo ̀baba rẹ̀: Ó ń sin àwọn ère baba rẹ̀ ń sìn, ó ń tẹrí rẹ̀ ba fún wọn. 22 Ó kọ Olúwa Ọlọ́run baba rẹ̀ sílẹ̀ rìn ̀ti Olúwa.

23 Àwọn ìránṣẹ́ Amoni dìtẹ̀ lórí rẹ̀ wọ́n lu ọba pa àárín ilé rẹ̀. 24 Nígbà náà àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pa gbogbo àwọn ó dìtẹ̀ ọba Amoni, wọ́n fi Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ààyè rẹ̀.

25 Àti gẹ́gẹ́ ìyókù iṣẹ́ ti ìjọba Amoni àti ohun ó ṣe, ṣé wọn kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn àwọn ọba Juda? 26 Wọ́n sin ín sínú isà òkú nínú ọgbà Ussa. Josiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também