Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 14

Amasiah ọba Juda

1 ọdún kejì Jehoaṣi ọmọ Joahasi ọba Israẹli, Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba. 2 14.2-6: 2Ki 25.1-4.Ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani; ó láti Jerusalẹmu. 3 Ó ṣe ohun ó tọ́ ojú Olúwa, ṣùgbọ́n í ṣe i Dafidi baba a rẹ̀ ṣe. Nínú ohun gbogbo, ó tẹ̀àpẹẹrẹ baba a rẹ̀ Joaṣi. 4 Àwọn ibi gíga ó ti ó , a i kúrò, àwọn ènìyàn tẹ̀síwájú láti ẹbọ àti sun tùràrí níbẹ̀.

5 Lẹ́yìn ó ti fi ọwọ́ gbá ìjọba rẹ̀ gbọingbọin, ó pa àwọn oníṣẹ́ wọ́n ti pa baba a rẹ̀ ọba. 6 Síbẹ̀ pa ọmọ àwọn apànìyàn náà. ìbámu pẹ̀ohun a kọ sínú ìwé òfin Mose níbi Olúwa ti paláṣẹ , "A yóò pa baba nítorí àwọn ọmọ, tàbí àwọn ọmọ nítorí àwọn baba; olúkúlùkù ni ó fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀."

7 14.7: 2Ki 25.11. Òun ni ẹni ó ṣẹ́gun ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ará Edomu àfonífojì iyọ̀, ó fi agbára Sela nínú ogun, ó ń é Jokteeli, orúkọ ó títí di òní.

8 14.8-14: 2Ki 25.17-24. Nígbà náà, Amasiah rán àwọn ìránṣẹ́ Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu ọba Israẹli pẹ̀ìpèníjà: ", jẹ́ á wo ara wa ojú."

9 Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì Amasiah ọba Juda: "Òṣùṣú kan Lebanoni rán iṣẹ́ kedari Lebanoni, Fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ìgbéyàwó.Nígbà náà ẹranko ẹlẹ́sẹ̀ mẹ́rin tinú igbó Lebanoni pẹ̀ó fi ẹsẹ̀ tẹ òṣùṣú náà mọ́lẹ̀. 10 Ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu pẹ̀, ṣùgbọ́n, nísinsin yìí ìwọ ṣe ìgbéraga. Ògo nínú ìṣẹ́gun rẹ, ṣùgbọ́n dúró nílé! ni ó o fi ń wàhálà o fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀?"

11 ó ti ó Amasiah tẹ́, bẹ́̀ ni Jehoaṣi ọba Israẹli dojúkọ ́. Òun àti Amasiah ọba Juda kọjú ara wọn Beti-Ṣemeṣi Juda. 12 A ipa ̀Juda nípasẹ̀ Israẹli, gbogbo àwọn ọkùnrin sálọ ilé e rẹ̀. 13 Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára Amasiah ọba Juda, ọmọ Jehoaṣi, ọmọ Ahasiah Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà, Jehoaṣi lọ Jerusalẹmu, ó lọ odi Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ìlẹ̀kùn Efraimu ibi igun ìlẹ̀kùn. Ìpín kan ó fẹ́rẹ̀ jẹ́ irinwó (400) ìgbọ̀nwọ́. 14 Ó gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun ó nínú ilé a kọ́ fún Olúwa àti níbi ìfowópamọ́ nínú ààfin ọba. Ó àwọn ògo, ó wọn padà Samaria.

15 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Jehoaṣi, gbogbo ohun ó ṣe pẹ̀àṣeyọrí rẹ̀, pẹ̀ogun rẹ̀ Amasiah ọba Juda, ṣé a kọ wọ́n inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli? 16 Jehoaṣi sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín Samaria pẹ̀àwọn ọba Israẹli. Jeroboamu ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

17 14.17-20: 2Ki 25.25-28. Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́̀́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli. 18 Fún ti ìyókù iṣẹ́ rẹ̀ nígbà ìjọba Amasiah, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda?

19 Wọ́n dìtẹ̀ i Jerusalẹmu, ó sálọ Lakiṣi, ṣùgbọ́n wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀e Lakiṣi, wọ́n pa á síbẹ̀. 20 Wọ́n gbé e padà pẹ̀ẹṣin, a sin ín Jerusalẹmu pẹ̀àwọn baba rẹ̀, ìlú ńlá ti Dafidi.

21 14.21,22: 2Ki 26.1,2. Nígbà náà, gbogbo àwọn ènìyàn Juda Asariah ó jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún. Wọ́n ṣe é ọba ìrọ́baba rẹ̀ Amasiah. 22 Òun ni ẹni ó tún Elati kọ́, ó a padà Juda lẹ́yìn Amasiah ti sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀.

Jeroboamu kejì ọba Israẹli

23 ọdún kẹ́̀dógún Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda, Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ọba Israẹli di ọba Samaria, ó jẹ ọba fún ̀kànlélógójì ọdún. 24 Ó ṣe búburú ojú Olúwa yípadà kúrò nínú ̀kankan nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati. Èyí ó ti fa Israẹli láti . 25 Òun ni ẹni ó ti àwọn ààlà Israẹli padà láti Lebo-Hamati òkú aginjù. ìbámu pẹ̀̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ Jona ọmọ Amittai, wòlíì láti Gati-Heferi.

26 Olúwa ti ìpọ́njú Israẹli , ó korò gidigidi, nítorí ẹrú tàbí òmìnira tàbí olùrànlọ́wọ́ kan fún Israẹli. 27 Láti ìgbà Olúwa ti òhun yóò bu àbùkù lu orúkọ Israẹli láti abẹ́ ̀run. Ó gbà wọ́n , lọ́wọ́ Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi.

28 Fún ti ìyókù iṣẹ́ ìjọba Jeroboamu, gbogbo ohun ó ṣe àti gbogbo àwọn agbára rẹ, ó ti jagun , àti ó ti gba Damasku àti Hamati, í ṣe ti Juda, padà fún Israẹli, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli? 29 Jeroboamu sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀, àwọn ọba Israẹli Sekariah ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também