Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 17

Hosea ọba ó gbẹ̀yìn Israẹli

1 ọdún kejìlá ọba Ahasi ará Juda, Hosea ọmọ Ela jẹ ọba Israẹli Samaria, ó jẹ fún ọdún mẹ́sàn-án. 2 Ó ṣe búburú ojú Olúwa, ṣùgbọ́n í ṣe i ti ọba Israẹli ẹni ó ti ṣáájú rẹ̀.

3 Ṣalamaneseri ọba Asiria sókè láti Hosea, ẹni ó ti jẹ fún Ṣalamaneseri ó ti san owó òde fún un. 4 Ṣùgbọ́n ọba Asiria i Hosea jẹ́ ọlọ́tẹ̀, nítorí ó ti rán oníṣẹ́ sọ́dọ̀ ọba Ejibiti, san owó òde mọ́ fún ọba Asiria, gẹ́gẹ́ o ti máa ń ṣe ọdọọdún. Nígbà náà ọba Asiria fi agbára ún, ó fi sínú túbú. 5 Ọba Asiria gòkè gbogbo ibi ilé náà, ó lọ Samaria, ó dúró ì fún ọdún mẹ́ta. 6 ọdún kẹsànán ti Hosea, ọba Asiria Samaria ó Israẹli lọ Asiria. Ó fi wọ́n sílẹ̀ Hala, Gosani etí odò Habori àti ìlú àwọn ará Media.

Israẹli kúrò ìlú nítorí ̀ṣẹ̀

7 Gbogbo eléyìí ṣẹlẹ̀ nítorí àwọn ọmọ Israẹli ti dẹ́ṣẹ̀ Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni ó wọn jáde Ejibiti lábẹ́ agbára Farao ọba Ejibiti. Wọ́n sin ọlọ́run mìíràn, 8 wọn si tẹ̀ìwà orílẹ̀-èdè Olúwa ti gbá kúrò níwájú wọn gẹ́gẹ́ ìwà ti ọba Israẹli ó ti paláṣẹ. 9 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun ìríra Olúwa Ọlọ́run wọn kọ́ láti ilé ìṣọ́ ìlú a dáàbò , wọ́n kọ́ ilé gíga fún ara wọn gbogbo ìlú wọn. 10 Wọ́n gbé àwọn òkúta a sọ́tọ̀ sókè àti ère òrìṣà Aṣerah lórí gbogbo igi tútù. 11 gbogbo ibi gíga, wọ́n sun tùràrí gẹ́gẹ́ orílẹ̀-èdè Olúwa ti jáde níwájú wọn. Wọ́n ṣe ohun búburú ó ìbínú Olúwa sókè. 12 Wọ́n sìn òrìṣà, èyí Olúwa ti sọ , "gbọdọ̀ ṣe èyí." 13 Olúwa kìlọ̀ fún Israẹli àti Juda nípa gbogbo àwọn wòlíì wọn àti aríran: "yípadà kúrò ̀búburú yín. ṣe òfin mi àti ìlànà mi, ìbámu pẹ̀gbogbo òfin Èmi paláṣẹ fún àwọn baba yín láti tẹ̀àti èyí mo rán i yín nípa ìránṣẹ́ àwọn wòlíì mi."

14 Ṣùgbọ́n wọn gbọ́, wọ́n ṣe gẹ́gẹ́ ọlọ́rùn líle gẹ́gẹ́ i ti baba wọn, ẹni gbà Olúwa Ọlọ́run wọn gbọ́. 15 Wọ́n kọ̀ ìlànà rẹ̀ àti májẹ̀ó ti ṣe pẹ̀baba wọn àti ìkìlọ̀ ó ti fi fún wọn. Wọ́n tẹ̀òrìṣà aláìníláárí, àwọn fún rara wọn jẹ́ aláìníláárí. Wọ́n tẹ̀orílẹ̀-èdè ó wọn ó tilẹ̀ jẹ́ Olúwa ti kìlọ̀ fún wọn , "ṣe ṣe gẹ́gẹ́ wọn ń ṣe," wọ́n ṣe ohun Olúwa ti léèwọ̀ fún wọn láti ṣe.

16 Wọ́n kọ̀ gbogbo òfin Olúwa Ọlọ́run wọn sílẹ̀, wọ́n ṣe òrìṣà méjì fún ara wọn, wọ́n gbẹ́ ̀kan ère ẹgbọrọ màlúù, àti ̀kan ère òrìṣà Aṣerah. Wọ́n tẹrí wọn ba gbogbo ogun ̀run, wọ́n sin Baali. 17 Wọ́n fi àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn ẹbọ nínú iná. Wọ́n ń fọ àfọ̀ṣẹ, wọ́n ń ṣe àlúpàyídà wọ́n ta ara wọn láti ṣe ohun búburú níwájú Olúwa, wọ́n un bínú.

18 Bẹ́̀ ni Olúwa bínú gidigidi pẹ̀Israẹli ó wọn kúrò níwájú rẹ̀. ̀Juda nìkan ṣoṣo ni ó , 19 àti pẹ̀, Juda pa òfin Olúwa Ọlọ́run wọn mọ́. Wọ́n tẹ̀ìhùwàsí àwọn Israẹli wọ́n ṣe. 20 Nítorí náà Olúwa kọ gbogbo àwọn ènìyàn Israẹli; ó jẹ wọ́n . Ó fi wọ́n ọwọ́ àwọn olè títí ó fi ta wọ́n kúrò níwájú rẹ̀.

21 Nígbà ó ta Israẹli kúrò láti ìdílé Dafidi, wọ́n Jeroboamu ọmọ Nebati jẹ ọba wọn. Jeroboamu àwọn ọmọ Israẹli yípadà kúrò títẹ̀Olúwa, ó wọn dẹ́ṣẹ̀ ńlá. 22 Àwọn ọmọ Israẹli forítì í nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ Jeroboamu padà kúrò lọ́dọ̀ wọn, 23 títí Olúwa fi wọn kúrò níwájú rẹ̀, gẹ́gẹ́ ó ti paláṣẹ láti ̀dọ̀ àwọn ìránṣẹ́ wòlíì. Bẹ́̀ ni a gbogbo ènìyàn Israẹli kúrò ilẹ̀ wọn lọ ìgbèkùn ni Asiria, títí di òní yìí.

Samaria tún fìdímúlẹ̀

24 Ọba Asiria àwọn ènìyàn láti Babeli, Kuta, Afa, Hamati àti Sefarfaimi, wọ́n fi wọ́n sínú ìlú Samaria láti rọ́àwọn ọmọ Israẹli. Wọ́n ń gbé ìlú náà. 25 Nígbà wọ́n gbé bẹ̀ àkọ́kọ́, wọn bẹ̀Olúwa, bẹ́̀ ni ó rán kìnnìún àárín wọn. Wọ́n pa nínú wọn. 26 Wọ́n sọ fún ọba Asiria , "Àwọn ènìyàn ìwọ kúrò o fi sínú ìlú Samaria mọ ohun ọlọ́run ìlú náà béèrè. Ó ti rán kìnnìún àárín wọn, ó ń pa wọ́n run, nítorí ènìyàn wọn mọ ohun ó béèrè."

27 Nígbà náà ọba Asiria pàṣẹ yìí , "̀kan lára àwọn àlùfáà ó láti Samaria lọ padà gbé níbẹ̀ ó kọ́ àwọn ènìyàn , ohun ọlọ́run ilẹ̀ náà béèrè." 28 Bẹ́̀ ni ̀kan lára àwọn àlùfáà ó ti kúrò Samaria gbé Beteli ó kọ́ wọn a ti ń sin Olúwa.

29 ó tilẹ̀ bẹ́̀, olúkúlùkù orílẹ̀-èdè ṣe òrìṣà tirẹ̀ gbogbo ìlú níbi wọ́n gbé , wọ́n gbé wọn nínú ilé òrìṣà àti àwọn ènìyàn Samaria ó ṣe wọ́n ibi gíga wọ̀n-ọn-nì. 30 Bẹ́̀ ni àwọn ọkùnrin láti Babeli ṣe àgọ́ àwọn wúńdíá, àwọn ènìyàn Kuti ṣe òrìṣà Nergali, àti àwọn ènìyàn Hamati ṣe ti Aṣima; 31 àti àwọn ará Afa ṣe Nibhasi àti Tartaki, àti àwọn ará Sefarfaimi sun àwọn ọmọ wọn níná gẹ́gẹ́ ẹbọ Adrameleki àti Anameleki, àwọn òrìṣà Sefarfaimi. 32 Wọ́n sin Olúwa, ṣùgbọ́n wọ́n tún yan gbogbo ẹgbẹ́ ènìyàn wọn láti ṣe iṣẹ́ oyè fún wọn gẹ́gẹ́ àlùfáà ibi gíga. 33 Wọ́n sin Olúwa ṣùgbọ́n wọ́n sin òrìṣà wọn ìṣọ̀kan pẹ̀àṣà orílẹ̀-èdè wọn láti ibi wọ́n ti gbé wọn .

34 Láti ìgbà náà àwọn àlùfáà wọn ṣe ti àtẹ̀yìnwá. Wọn sin Olúwa tàbí wọ́n fi ara mọ́ ìlànà àti àṣẹ àti òfin Olúwa fi fún ìránṣẹ́ Jakọbu, wọ́n pe orúkọ rẹ̀ Israẹli. 35 Nígbà Olúwa ṣe májẹ̀pẹ̀àwọn ọmọ Israẹli ó pàṣẹ fún wọn , "ṣe sin òrìṣà mìíràn tàbí tẹríba fún wọn, sìn wọ́n tàbí ẹbọ wọn. 36 Ṣùgbọ́n Olúwa, ẹni ó yín gòkè jáde láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀agbára ńlá àti nínà apá, òun ni ẹni náà ó yẹ sìn. Òun ni ẹni ó yẹ tẹríba fún àti òun ni ẹbọ fún. 37 Ó yẹ ̀yin ó máa kíyèsi ara yín gidigidi láti pa ìlànà àti àṣẹ, àti òfin ó kọ fún un yín mọ́. ṣe sin ọlọ́run mìíràn. 38 ṣe gbàgbé májẹ̀mo ti ṣe pẹ̀yín mọ́ àti sin ọlọ́run mìíràn. 39 Kúkú sin Olúwa Ọlọ́run rẹ; Òun ni ẹni náà yóò gbà yín kúrò lọ́wọ́ gbogbo àwọn ̀a yín."

40 Wọn gbọ́, bẹ́̀ ni, wọ́n ń ṣe iṣẹ́ wọ́n ti àtijọ́. 41 Bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn wọn sin Olúwa, wọ́n ń sin òrìṣà wọn. Títí di ọjọ́ òní ọmọ wọn àti àwọn ọmọ ọmọ wọn ń ṣe àwọn baba wọn ti ń ṣe.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também