Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 9

A fi àmì òróró yàn Jehu ọba Israẹli

1 9.1–10.36: 2Ki 22.7-9. Wòlíì Eliṣa fi àṣẹ pe ọkùnrin kan láti ẹgbẹ́ àwọn wòlíì, ó fún un , "Ki agbádá rẹ sínú ̀àmùrè rẹ, gba ṣágo kékeré òróró yìí pẹ̀rẹ, o lọ Ramoti Gileadi. 2 Nígbà o bẹ̀, Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi kiri. Lọ ̀dọ̀ rẹ̀, un kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, o un wọ inú yàrá lọ́hùn ún lọ. 3 Nígbà náà, ṣágo kékeré yìí, o da òróró náà e lórí, o , Èyí ni ohun Olúwa , "Èmi fi àmì òróró yàn ́ ọba lórí Israẹli." Nígbà náà, ṣí ìlẹ̀kùn, o sáré, ṣe jáfara!"

4 Bẹ́̀ ni ̀dọ́mọkùnrin náà, wòlíì náà lọ Ramoti Gileadi. 5 Nígbà ó , ó àwọn olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun wọ́n jókòó papọ̀. "Èmi iṣẹ́ fún , olórí," Ó .

"ta ni nínú wa?" Jehu béèrè.

Òun , ", balógun," Ó dáhùn.

6 Jehu dìde sókè, ó wọ inú ilé lọ. Nígbà náà, wòlíì náà da òróró náà sórí Jehu; ó , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli : Èmi fi àmì òróró yàn ́ ọba lórí àwọn ènìyàn Olúwa Israẹli. 7 ìwọ ó pa ilé Ahabu ̀à rẹ̀ run, Èmi yóò gbẹ̀san ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì àti gbogbo ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ Olúwa a ta sílẹ̀ látọwọ́ Jesebeli. 8 Gbogbo ilé Ahabu yóò ṣègbé. Èmi yóò e kúrò láti orí Ahabu gbogbo ̀dọ́mọkùnrin ó gbẹ̀yìn ni Israẹli, ẹrú tàbí òmìnira. 9 Èmi yóò ṣe ilé Ahabu gẹ́gẹ́ ilé Jeroboamu ọmọ Nebati àti ilé Baaṣa ọmọ Ahijah. 10 Fún Jesebeli, ajá ni yóò jẹ ́ oko Jesreeli, ẹni yóò sin òkú rẹ̀.’ " Nígbà náà ó ṣí ìlẹ̀kùn, ó sálọ.

11 Nígbà Jehu jáde lọ àwọn ọgbà ìjòyè e rẹ̀, ̀kan nínú wọn bi í , "Ṣé gbogbo nǹkan dára?"

ni ó aṣiwèrè fi tọ̀ ́ , "Ìwọ mọ ọkùnrin náà àti irú nǹkan ó ń sọ," Jehu fèsì.

12 "Ìyẹn í ṣe òótọ́!" Wọ́n . "Sọ fún wa."

Jehu , "Èyí ni ohun ó sọ fún mi: Èyí ni ohun Olúwa , "Èmi fi àmì òróró yàn ́ ọba lórí Israẹli." ’ "

13 Wọ́n ṣe gírí, wọ́n agbádá a wọn, wọ́n tàn wọ́n abẹ́ rẹ̀ orí àtẹ̀gùn. Nígbà náà, wọ́n fọn ìpè, wọ́n kígbe, "Jehu jẹ ọba!"

Jehu pa Joramu àti Ahasiah

14 Bẹ́̀ ni Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi, dìtẹ̀ Joramu. (Nísinsin yìí Joramu àti gbogbo Israẹli ti ń dáàbò bo Ramoti Gileadi nítorí Hasaeli ọba Aramu. 15 ṣùgbọ́n ọba Joramu ti padà Jesreeli láti lọ sàn nínú ọgbẹ́ àwọn ará Aramu ti i lára nínú ogun pẹ̀ọba Hasaeli ti Aramu.) Jehu , "èyí jẹ́ ̀ò ń , ṣe jẹ́ ẹnìkankan ó yọ jáde nínú ìlú ńlá láti lọ sọ ìròyìn náà Jesreeli." 16 Nígbà náà Jehu wọ inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ó gùn ún lọ Jesreeli, nítorí Joramu ń sinmi níbẹ̀ àti Ahasiah ọba Juda sọ̀kalẹ̀ láti Joramu.

17 Nígbà olùṣọ́ kan ó dúró ilé ìṣọ́ Jesreeli, ̀wọ́ ogun Jehu wọ́n ń súnmọ́ tòsí, ó jáde, "Mo àwọn ̀wọ́ ogun ó ń bọ̀."

"ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kan," Joramu pa á láṣẹ. "Rán an lọ ̀dọ̀ wọn o béèrè , Ṣé ̀yin pẹ̀àlàáfíà?’ "

18 Ọkùnrin ẹlẹ́ṣin náà, lọ láti lọ Jehu ó , "Èyí ni ohun ọba : Ṣé ìwọ pẹ̀àlàáfíà?’ "

"ni ìwọ ṣe pẹ̀àlàáfíà?" Jehu dáhùn. "Bọ́ ̀yìn mi."

Olùṣọ́ náà fún un , "Ìránṣẹ́ náà ti ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n tún padà mọ́."

19 Bẹ́̀ ni, ọba rán ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kejì. Nígbà náà ó ̀dọ̀ wọn, ó , "Èyí ni ohun ọba sọ:

"Ṣé ìwọ pẹ̀àlàáfíà?" Jehu dáhùn, "Dúró ̀yìn mi."

20 Olùṣọ́ náà fi sùn. "Ó ti ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n tún padà mọ́ pẹ̀. Wíwá rẹ̀ dàbí ti Jehu ọmọ Nimṣi, ó ń wa kẹ̀kẹ́ ti aṣiwèrè."

21 "Fi ìwọ̀ kọ́ kẹ̀kẹ́ ogun mi." Joramu pa á láṣẹ. Àti nígbà a fi kọ́, Joramu ọba Israẹli àti Ahasiah ọba Juda, gun kẹ̀kẹ́ lọ, olúkúlùkù nínú kẹ̀kẹ́ ogun tirẹ̀, láti lọ Jehu. Wọ́n a pàdé ibi oko ó ti jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli. 22 Nígbà Joramu Jehu, ó béèrè , "Ṣé ìwọ pẹ̀àlàáfíà, Jehu?"

"Báwo ni àlàáfíà yóò ṣe ," Jehu dáhùn, "ìwọ̀n ìgbà gbogbo ìbọ̀rìṣà àti iṣẹ́ àjẹ́ ti màmá rẹ Jesebeli di púpọ̀?"

23 Joramu ọwọ́ rẹ̀ padà, ó sálọ, ó ń pe Ahasiah, "̀tẹ̀ , Ahasiah!"

24 Nígbà náà, Jehu fa ọrun rẹ̀, ó yin Joramu láàrín èjìká méjèèjì. Ọfà náà wọ inú ọkàn rẹ̀, ó ṣubú lulẹ̀ láti orí kẹ̀kẹ́ rẹ̀. 25 9.25: On 21.19.Jehu sọ fún Bidikari, balógun kẹ̀kẹ́ rẹ̀ , "Gbé e sókè ó ú orí oko ó jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli. Rántí èmi àti ìwọ ti ń gun kẹ̀kẹ́ papọ̀ lẹ́yìn Ahabu baba à rẹ nígbà Olúwa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀, 26 àná, mo ̀jẹ̀ Naboti pẹ̀̀jẹ̀ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ni Olúwa .Ǹjẹ́ nítorí náà, gbé e sókè, o ú orí ilẹ̀ oko náà ìbámu pẹ̀̀rọ̀ Olúwa."

27 Nígbà Ahasiah ọba, Juda ohun ó ti ṣẹlẹ̀, ó sálọ sójú ̀Beti-Haggani. Jehu lépa rẹ̀, ó ń kígbe, "Pa á pẹ̀!" Wọ́n ṣá a ọgbẹ́ nínú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ̀lọ Guri lẹ́bàá a Ibleamu, ṣùgbọ́n ó sálọ Megido, ó síbẹ̀. 28 Ìránṣẹ́ rẹ̀ gbé e pẹ̀kẹ̀kẹ́ lọ Jerusalẹmu, ó sin ín pẹ̀, baba a rẹ̀ nínú ibojì rẹ̀ ìlú ńlá ti Dafidi. 29 (ọdún kọkànlá ti Joramu ọmọ Ahabu, Ahasiah ti di ọba Juda.)

A pa Jesebeli

30 Nígbà náà Jehu lọ Jesreeli. Nígbà Jesebeli gbọ́ nípa rẹ̀, ó kun ojú u rẹ̀, ó to irun rẹ̀, ó jáde láti ojú fèrèsé. 31 Jehu ti wọ ẹnu ìlẹ̀kùn, ó béèrè, "Ṣé ìwọ àlàáfíà, Simri, ìwọ olùpa ̀à rẹ?"

32 Ó gbójú sókè láti wo fèrèsé, ó jáde, "Ta ni ó ̀gbẹ́ mi? Ta ni?" Ìwẹ̀méjì tàbí mẹ́ta bojú ó nílẹ̀. 33 Jehu sọ , "Gbé e sílẹ̀!" Wọ́n ú sílẹ̀. Díẹ̀ nínú ̀jẹ̀ rẹ̀ fọ́n ara ògiri àti àwọn ẹṣin wọ́n ti tẹ̀ ́ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ wọn.

34 Jehu wọ inú ilé lọ, ó jẹ, ó mu. "Tọ́obìnrin yẹn a fi ," Ó , "o sin ín, nítorí ọmọbìnrin ọba ni ó jẹ́." 35 Ṣùgbọ́n nígbà wọ́n jáde lọ láti lọ sin ín, wọn nǹkan kan àyàfi agbárí i rẹ̀, ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì àti ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì. 36 9.36: On 21.23.Wọ́n padà lọ sọ fún Jehu, ẹni ó , "Èyí ni ̀rọ̀ Olúwa ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah ará Tiṣibi , orí oko Jesreeli ni àwọn ajá yóò ti jẹ ẹran-ara Jesebeli. 37 Òkú Jesebeli yóò dàbí ohun ̀gbin orí oko Jesreeli, bi , ẹnikẹ́ni yóò sọ , "Jesebeli ni èyí." ’ "

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também