Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 15

Asariah ọba Juda

1 ọdún kẹtàdínlọ́gbọ̀n Jeroboamu ọba Israẹli, Asariah ọmọ Amasiah ọba Juda bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba. 2 15.2,3: 2Ki 26.3,4.Ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́rìndínlógún nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún méjìléláàádọ́ta. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jekoliah; ó láti Jerusalẹmu. 3 Ó ṣe ohun ó dára lójú Olúwa, gẹ́gẹ́ baba rẹ̀ Amasiah ti ṣe. 4 Àwọn ibi gíga, ó ti ó , a ṣí wọn kúrò, àwọn ènìyàn náà tẹ̀síwájú láti máa ẹbọ àti sun tùràrí níbẹ̀.

5 15.5-7: 2Ki 26.20-23. Olúwa kọlu ọba náà pẹ̀̀tẹ̀, títí di ọjọ́ ó , ó ń gbé ilé ̀tọ̀. Jotamu, ọmọ ọba tọ́ààfin, ó ń darí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà.

6 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Asariah, pẹ̀gbogbo ohun ó ṣe, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda. 7 Asariah sinmi pẹ̀àwọn baba a rẹ̀. A sin ín ̀wọn ìlú ńlá ti Dafidi. Jotamu ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Sekariah ọba Israẹli

8 ọdún kejìdínlógójì Asariah ọba Juda. Sekariah ọmọ Jeroboamu di ọba Israẹli Samaria, ó jẹ ọba fún oṣù mẹ́. 9 Ó ṣe búburú lójú Olúwa, gẹ́gẹ́ àwọn baba rẹ̀ ṣe. yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí ó ti fa Israẹli láti .

10 Ṣallumu ọmọ Jabesi dìtẹ̀ Sekariah. Ó dojúkọ ́ níwájú àwọn ènìyàn, ó pa á, ó jẹ ọba dípò rẹ̀. 11 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Sekariah. Wọ́n kọ ́ sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli. 12 Bẹ́̀ ni ̀rọ̀ Olúwa a sọ fún Jehu jẹ́ ìmúṣẹ: "Àwọn ọmọ rẹ̀ yóò jókòó lórí ìtẹ́ Israẹli títí ìran kẹrin."

Ṣallumu ọba Israẹli

13 Ṣallumu ọmọ Jabesi di ọba ọdún kọkàndínlógójì Ussiah ọba Juda, ó jẹ ọba Samaria fún oṣù kan. 14 Nígbà náà Menahemu ọmọ Gadi lọ láti Tirsa Samaria. Ó dojúkọ Ṣallumu ọmọ Jabesi Samaria, ó pa á ó rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

15 Fún ti ìyókù iṣẹ́ ìjọba Ṣallumu, àti ìdìtẹ̀ ó , a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli.

16 ìgbà Menahemu ń jáde bọ̀ láti Tirsa, ó dojúkọ Tifisa àti gbogbo ènìyàn ó ìlú ńlá àti agbègbè rẹ̀, nítorí wọn kọ̀ láti ẹnu ibodè. Ó yọ Tifisa kúrò lẹ́nu iṣẹ́, ó la inú gbogbo àwọn obìnrin aboyún.

Menahemu ọba Israẹli

17 ọdún kọkàndínlógójì ti Asariah ọba Juda, Menahemu ọmọ Gadi di ọba Israẹli, ó jẹ ọba Samaria fún ọdún mẹ́wàá. 18 Ó ṣe búburú lójú Olúwa, gbogbo ìjọba rẹ̀. yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí ó ti fa Israẹli láti .

19 Nígbà náà, Pulu ọba Asiria, gbógun ti ilẹ̀ náà, Menahemu fún un ẹgbẹ̀rin (1,000) tálẹ́ǹtì fàdákà láti fi gba àtìlẹ́yìn rẹ̀ àti láti fún ìdúró tirẹ̀ lágbára lórí ìjọba. 20 Menahemu fi agbára gba owó náà lọ́wọ́ Israẹli. Gbogbo ọkùnrin ọlọ́láti àádọ́ta ṣékélì fàdákà láti fún ọba Asiria. Bẹ́̀ ni ọba Asiria padà sẹ́yìn, dúró ilẹ̀ náà mọ́.

21 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Menahemu, àti gbogbo ohun ó ṣe, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé ọba Israẹli? 22 Menahemu sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀. Pekahiah ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Pekahiah ọba Israẹli

23 ọdún kẹ́̀dógún Asariah ọba Juda, Pekahiah ọmọ Menahemu di ọba Israẹli Samaria, ó jẹ ọba fún ọdún méjì. 24 Pekahiah ṣe búburú lójú Olúwa. yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí ó fa Israẹli láti . 25 ̀kan lára àwọn olórí ìjòyè rẹ̀ Peka ọmọ Remaliah, dìtẹ̀ i. Ó àádọ́ta àwọn ọkùnrin ti àwọn ará Gileadi pẹ̀u rẹ̀. Ó pa Pekahiah pẹ̀Argobu àti Arie odi ààfin ọba Samaria. Bẹ́̀ ni Peka pa Pekahiah, ó jẹ ọba ipò rẹ̀.

26 Fún ti ìyókù iṣẹ́ ìjọba Pekahiah, gbogbo ohun ó ṣe, ni a kọ sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli.

Peka ọba Israẹli

27 ọdún kejìléláàádọ́ta Asariah ọba Juda, Peka ọmọ Remaliah di ọba Israẹli Samaria. Ó jẹ ọba fún ogún ọdún. 28 Ó ṣe búburú lójú Olúwa, yípadà kúrò nínú ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí ó fa Israẹli láti .

29 ìgbà Peka ọba Israẹli, Tiglat-Pileseri ọba Asiria , ó Ijoni, Abeli-Beti-Maaka, Janoa, Kedeṣi àti Hasori. Ó gba Gileadi àti Galili pẹ̀gbogbo ilẹ̀ Naftali. Ó àwọn ènìyàn ìgbèkùn lọ Asiria. 30 Nígbà náà, Hosea ọmọ Ela, dìtẹ̀ Peka ọmọ Remaliah. Ó dojúkọ ́, ó pa á, ó rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba ogún ọdún Jotamu ọmọ Ussiah.

31 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Peka, àti gbogbo ohun ó ṣe, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?

Jotamu ọba Juda

32 ọdún keje Peka ọmọ Remaliah ọba Israẹli, Jotamu ọmọ Ussiah ọba Juda bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba. 33 15.33-35: 2Ki 27.1-3.Ó jẹ́ ẹni ọdún mẹ́̀́dọ́gbọ̀n nígbà ó di ọba. Ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́rìndínlógún. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jeruṣa ọmọbìnrin Sadoku. 34 Ó ṣe ohun ó tọ́ lójú Olúwa gẹ́gẹ́ baba a rẹ̀ Ussiah ti ṣe. 35 Àwọn ibi gíga, ó ti ó , a ṣí wọn kúrò àwọn ènìyàn tẹ̀síwájú láti ẹbọ àti láti sun tùràrí níbẹ̀: Jotamu tún ìlẹ̀kùn gíga ń kọ́ ti ilé a kọ́ fún Olúwa ṣe.

36 Fún ti ìyókù iṣẹ́ nígbà ìjọba Jotamu, àti ohun ó ṣe, ṣé a kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Juda? 37 (ayé ìgbàanì, Olúwa bẹ̀rẹ̀ rán Resini ọba Siria àti Peka ọmọ Remaliah láti dojúkọ Juda). 38 15.38: 2Ki 27.9.Jotamu sinmi pẹ̀àwọn baba rẹ̀. A sin ín pẹ̀wọn ìlú ńlá Dafidi, ìlú ńlá ti baba rẹ̀. Ahasi ọmọ rẹ̀ rọ́rẹ̀ gẹ́gẹ́ ọba.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também