Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 16

Ahasi ọba Juda

1 ọdún kẹtàdínlógún Peka ọmọ Remaliah, Ahasi ọmọ Jotamu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ i jẹ ọba. 2 16.2-4: 2Ki 28.1-4.Ẹni ogún ọdún ni Ahasi nígbà ó bẹ̀rẹ̀ jẹ ọba, ó jẹ ọba ọdún mẹ́rìndínlógún Jerusalẹmu, ṣe èyí ó tọ́ lójú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ Dafidi baba rẹ̀. 3 Ṣùgbọ́n ó rìn ̀àwọn ọba Israẹli, nítòótọ́, ó sun ọmọ rẹ̀ nínú iná, gẹ́gẹ́ ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè, Olúwa jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli. 4 Ó ẹbọ, ó sun tùràrí àwọn ibi gíga, àti lórí àwọn òkè kéékèèké àti lábẹ́ gbogbo igi tútù.

5 Nígbà náà ni Resini ọba Siria àti Peka ọmọ Remaliah ọba Israẹli gòkè Jerusalẹmu láti jagun: wọ́n ti Ahasi, ṣùgbọ́n wọn borí rẹ̀. 6 àkókò náà, Resini ọba Siria gba Elati padà fún Siria, ó àwọn ènìyàn Juda kúrò Elati: àwọn ará Siria Elati, wọ́n ń gbé ibẹ̀ títí di òní yìí.

7 Ahasi rán oníṣẹ́ sọ́dọ̀ Tiglat-Pileseri ọba Asiria , "Ìránṣẹ́ rẹ ni èmi, àti ọmọ rẹ; gòkè , o gbà mi lọ́wọ́ ọba Siria, àti lọ́wọ́ ọba Israẹli ó dìde mi." 8 Ahasi fàdákà àti wúrà a ilé Olúwa, àti nínú ìṣúra ilé ọba, ó rán an ọba Asiria ọrẹ. 9 Ọba Asiria gbọ́ tirẹ̀: nítorí ọba Asiria gòkè Damasku, ó o, ó un ìgbèkùn lọ Kiri, ó pa Resini.

10 Ọba lọ Damasku láti pàdé Tiglat-Pileseri, ọba Asiria, ó pẹpẹ kan ó Damasku: Ahasi ọba rán àwòrán pẹpẹ náà, àti àpẹẹrẹ rẹ̀ Uriah àlùfáà, gẹ́gẹ́ gbogbo iṣẹ́ ̀rẹ̀. 11 Uriah àlùfáà kọ́ pẹpẹ náà gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí Ahasi ọba fi ránṣẹ́ i láti Damasku; bẹ́̀ ni Uriah àlùfáà ṣe é ìpadàbọ̀ Ahasi ọba láti Damasku. 12 Nígbà ọba ti Damasku , ọba pẹpẹ náà: ọba súnmọ́ pẹpẹ náà, ó ẹbọ lórí rẹ̀. 13 Ó sun ẹbọ sísun rẹ̀ àti ọrẹ-jíjẹ rẹ̀, o si ta ohun mímu rẹ̀ sílẹ̀, ó wọ́n ̀jẹ̀ ọrẹ àlàáfíà rẹ̀ ara pẹpẹ náà. 14 Ṣùgbọ́n ó pẹpẹ idẹ ó níwájú Olúwa kúrò láti iwájú ilé náà, láti àárín méjì pẹpẹ náà, àti ilé Olúwa, ó fi í apá àríwá pẹpẹ náà.

15 Ahasi ọba pàṣẹ fún Uriah àlùfáà, , "Lórí pẹpẹ ńlá náà ni o máa sun ẹbọ sísun òròwúrọ̀ àti ọrẹ-jíjẹ alaalẹ́, àti ẹbọ sísun ti ọba, àti ọrẹ-jíjẹ rẹ̀, pẹ̀ẹbọ sísun gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti ọrẹ-jíjẹ wọn, àti ọrẹ ohun mímu wọn; o wọ́n gbogbo ̀jẹ̀ ẹbọ sísun náà lórí rẹ̀, àti gbogbo ̀jẹ̀ ẹbọ mìíràn, ṣùgbọ́n ti pẹpẹ idẹ náà èmi ó máa gbèrò ohun èmi ó fi ṣe." 16 Báyìí ni Uriah àlùfáà ṣe, gẹ́gẹ́ gbogbo èyí Ahasi ọba pàṣẹ.

17 Ahasi ọba igi-ìpílẹ̀ àwọn àgbédúró náà, ó ṣí agbada náà kúrò lára wọn; ó gbé agbada ńlá náà kalẹ̀ kúrò lára àwọn màlúù idẹ ń bẹ lábẹ́ rẹ̀, ó gbé e ka ilẹ̀ a fi òkúta tẹ́. 18 Ibi ààbò fún ọjọ́ ìsinmi a kọ́ nínú ilé náà, àti ̀ìjáde òde ọba, ni ó yípadà kúrò ilé Olúwa nítorí ọba Asiria.

19 Àti ìyókù ìṣe Ahasi ó ṣe, a ha kọ wọ́n sínú ìwé ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? 20 16.20: 2Ki 28.27.Ahasi sùn pẹ̀àwọn baba rẹ̀, a sin ín pẹ̀àwọn baba rẹ̀ ìlú Dafidi: Hesekiah ọmọ rẹ̀ jẹ ọba ipò rẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também