Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 5

Ìwòsàn Naamani adẹ́tẹ̀

1 Naamani jẹ́ olórí ogun ọba Aramu. Ó jẹ́ ènìyàn ńlá níwájú ̀rẹ̀, wọ́n bu ọlá fún un, nítorí nípasẹ̀ rẹ̀ ni Olúwa ti fi ìṣẹ́gun fún Aramu. Òun jẹ́ alágbára, akọni ọkùnrin ṣùgbọ́n, ó dẹ́tẹ̀.

2 Nísinsin yìí ẹgbẹgbẹ́ láti Aramu ti jáde lọ láti ọmọ obìnrin kékeré kan ìgbèkùn láti Israẹli, ó sin ìyàwó Naamani. 3 Ó sọ fún ̀rẹ̀ obìnrin , "ó jẹ́ ̀mi wòlíì ó Samaria! Yóò ó sàn kúrò nínú ̀tẹ̀ rẹ̀."

4 Naamani lọ ̀dọ̀ ̀rẹ̀ ó fún un ohun ọmọbìnrin Israẹli ti sọ. 5 "gbogbo ̀, lọ," ọba Aramu a lóhùn , "Èmi yóò fi ìwé ránṣẹ́ ọba Israẹli." Bẹ́̀ ni Naamani lọ, ó pẹ̀rẹ̀ tálẹ́ǹtì fàdákà mẹ́wàá, ẹgbẹ̀rún mẹ́(6,000) ìwọ̀n wúrà àti ìpààrọ̀ aṣọ mẹ́wàá. 6 Ìwé ó lọ sọ́dọ̀ ọba Israẹli , "Pẹ̀ìwé yìí èmi ń rán ìránṣẹ́ mi Naamani o ó sàn kúrò nínú ̀tẹ̀ rẹ̀."

7 ọba Israẹli ti ka ìwé náà ó fa aṣọ rẹ̀ ya, ó , "Èmi ha jẹ́ Ọlọ́run? Ǹjẹ́ èmi le pa n ààyè padà? ni ó eléyìí rán ènìyàn mi láti wo ààrùn ̀tẹ̀ rẹ sàn, wo ó ti ń ̀láti ìjà pẹ̀mi!"

8 Nígbà Eliṣa ènìyàn Ọlọ́run gbọ́ ọba Israẹli ti ya aṣọ rẹ̀, ó rán iṣẹ́ yìí i , "ni ó o fi fa aṣọ rẹ ya? Jẹ́ ọkùnrin náà ̀dọ̀ mi. Òun yóò mọ̀ wòlíì Israẹli." 9 Bẹ́̀ ni Naamani lọ pẹ̀ẹṣin rẹ̀ àti kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó dúró ẹnu-ọ̀ilé Eliṣa. 10 Eliṣa rán ìránṣẹ́ láti lọ sọ fún un , "Lọ, wẹ̀ ara rẹ ìgbà méje odò Jordani, ẹran-ara rẹ yóò tún padà bọ̀ sípò, ìwọ yóò mọ́."

11 Ṣùgbọ́n Naamani lọ pẹ̀ìbínú ó , "Mo lérò yóò dìde jáde nítòótọ́ mi, yóò pe orúkọ Olúwa Ọlọ́run, fi ọwọ́ rẹ̀ lórí ibẹ̀ ó wo ̀tẹ̀ mi sàn. 12 Abana àti Fapari, odò Damasku ha dára ju gbogbo omi Israẹli lọ? Ṣé èmi le wẹ̀ nínú wọn n mọ́?" Bẹ́̀ ni ó yípadà, ó lọ pẹ̀ìrunú.

13 Ìránṣẹ́ Naamani lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó , "Baba mi, wòlíì ti sọ fún láti ṣe ohun ńlá kan, ṣé ìwọ ti ṣe, mélòó mélòó nígbà náà, nígbà ó sọ fún , Wẹ̀ o mọ́’!" 14 Bẹ́̀ ni ó sọ̀kalẹ̀ lọ ó tẹ ara rẹ̀ bọ inú odò Jordani ìgbà méje, gẹ́gẹ́ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ fún un, ẹran-ara rẹ̀ tún padà mímọ́ gẹ́gẹ́ ọmọkùnrin kékeré.

15 Nígbà náà Naamani àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ padà lọ ̀dọ̀ ènìyàn Ọlọ́run. Ó dúró níwájú rẹ̀ ó , "Nísinsin yìí èmi mọ̀ Ọlọ́run gbogbo àgbáyé àyàfi Israẹli nìkan. Jọ̀wọ́ gba ̀bùn láti ọwọ́ ìránṣẹ́ rẹ."

16 Wòlíì náà dáhùn , "Gẹ́gẹ́ Olúwa ti ń bẹ láààyè, ẹni mo ń sìn, èmi nígbà ohun kan," ó tilẹ̀ jẹ́ Naamani rọ̀ ́ láti gbà á, ó kọ̀.

17 Naamani , "o nígbà, jọ̀wọ́ jẹ́ a fi fún èmi ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ ̀pọ̀ ẹrù erùpẹ̀ ìbáaka méjì le , nítorí láti òní lọ ìránṣẹ́ rẹ yóò ẹbọ sísun àti ẹbọ ̀kan lára àwọn ọlọ́run mìíràn mọ́ ṣe Olúwa. 18 Ṣùgbọ́n Olúwa ó dáríjì ìránṣẹ́ rẹ fún nǹkan yìí. Nígbà ̀mi wọ inú ilé Rimoni láti fi orí balẹ̀ ó fi ara ti ọwọ́ mi mo tẹ ara mi ba pẹ̀níbẹ̀. Nígbà èmi tẹ ara mi ba ilé Rimoni, Olúwa dáríjì ìránṣẹ́ rẹ fún èyí."

19 Eliṣa , "Máa lọ àlàáfíà."

Lẹ́yìn ìgbà Naamani rin ìrìnàjò ó jìnnà, 20 Gehasi, ìránṣẹ́ Eliṣa ènìyàn Ọlọ́run, ó fún ara rẹ̀ , "̀mi jẹ́ ẹni ó rọ́lórí Naamani, ará Aramu, nípa gba ohunkóhun ọwọ́ rẹ̀ ohun ó , gẹ́gẹ́ Olúwa ti ń bẹ láààyè, èmi yóò tẹ̀e èmi yóò gba ohun kan ọwọ́ rẹ̀."

21 Bẹ́̀ ni Gehasi sáré tẹ̀Naamani. Nígbà Naamani i ó ń sáré tẹ̀e, ó sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́ láti pàdé rẹ̀. "Ṣé gbogbo nǹkan dáradára?" ó béèrè.

22 "Gbogbo nǹkan dáradára," Gehasi a lóhùn. "̀mi rán mi láti sọ , Àwọn ̀dọ́ ọmọkùnrin méjì láti ̀dọ̀ ọmọ wòlíì wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ ̀dọ̀ mi láti orí òkè ìlú ti Efraimu. Jọ̀wọ́ fún wọn ̀bùn fàdákà àti ìpààrọ̀ aṣọ méjì.’ "

23 Naamani , "gbogbo ̀, ̀bùn méjì." Ó rọ Gehasi láti gbà wọ́n, ó di ̀bùn méjì náà ti fàdákà inú àpò méjì, pẹ̀ìpààrọ̀ aṣọ méjì, ó fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ méjì, wọ́n wọn lọ sọ́dọ̀ Gehasi. 24 Nígbà Gehasi ibi ilé ìṣọ́, ó gbà wọ́n lọ́wọ́ wọn, ó wọ́n sínú ilé, ó jọ̀wọ́ àwọn ọkùnrin náà lọ́wọ́ lọ, wọ́n jáde lọ. 25 Nígbà náà ó wọlé ó dúró níwájú ̀rẹ̀ Eliṣa.

"Níbo ni o ti Gehasi?" Eliṣa béèrè.

"Ìránṣẹ́ rẹ lọ ibìkan kan." Gehasi a lóhùn.

26 Ṣùgbọ́n Eliṣa fún un , "̀mi ha pẹ̀rẹ nígbà ọkùnrin náà sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́ láti pàdé rẹ? Ṣé àsìkò ó yẹ láti gba owó nìyìí, tàbí láti gba aṣọ, ọgbà olifi, ọgbà àjàrà, àgùntàn, màlúù tàbí ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin? 27 ̀tẹ̀ Naamani yóò lẹ̀ mọ́ àti irú-ọmọ rẹ títí láé." Nígbà náà Gehasi kúrò níwájú Eliṣa, ó di adẹ́tẹ̀, ó funfun gẹ́gẹ́ ̀gbọ̀n òwú.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também