Pular para o conteúdo
Publicidade

2 Ọba 22

A ìwé òfin

1 22.1,2: 2Ki 34.1,2. Josiah jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ nígbà ó di ọba, ó jẹ ọba Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jedida ọmọbìnrin Adaiah; ó láti Boskati. 2 Ó ṣe èyí ó dára lójú Olúwa, ó rìn ̀Dafidi baba a rẹ̀, yípadà apá ̀tún tàbí apá òsì.

3 22.3-7: 2Ki 34.8-12. ọdún kejìdínlógún ó fi jẹ ọba. Ọba Josiah rán akọ̀, Ṣafani ọmọ Asalia, ọmọ Meṣullamu, ilé Olúwa. Ó , 4 "Gòkè lọ ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, o jẹ́ ó ṣírò iye owó a ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ti gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn. 5 jẹ́ wọn ó fi àwọn ọkùnrin a ti yàn láti bojútó iṣẹ́ náà lórí ilé Olúwa. jẹ́ àwọn ọkùnrin san án fún àwọn òṣìṣẹ́ ó ń tún ilé Olúwa ṣe. 6 Àwọn gbẹ́nàgbẹ́, àwọn ̀mọ̀àti àwọn akọ́. Bákan náà ni wọ́n ra igi àti òkúta ọlọ́ṣọ̀́ láti fi tún tẹmpili ṣe. 7 Ṣùgbọ́n wọn láti ṣe ìṣirò fún owó náà a fi fún wọn, nítorí wọ́n ṣe òtítọ́."

8 Hilkiah olórí àlùfáà sọ fún Ṣafani akọ̀, "Èmi ìwé òfin nílé Olúwa." Ó fi fún Ṣafani, ẹni ó á. 9 Nígbà náà, Ṣafani akọ̀lọ ̀dọ̀ ọba. Ó sọ fún un , "Àwọn ìjòyè rẹ ti san owó náà ó nínú ilé Olúwa. Èmi ti fi ọwọ́ àwọn ó ń ṣe iṣẹ́ náà àti àwọn alábojútó nílé Olúwa." 10 Nígbà náà Ṣafani akọ̀sọ fún ọba , "Hilkiah àlùfáà ti fún un ìwé kan." Ṣafani lára rẹ̀ níwájú ọba.

11 Nígbà ọba gbọ́ ̀rọ̀ ó nínú ìwé òfin, ó fa aṣọ rẹ̀ ya. 12 Ó pa àṣẹ yìí fún Ahikamu àlùfáà, Hilkiah ọmọ Ṣafani, Akbori ọmọ Mikaiah, àti Ṣafani akọ̀àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba. 13 "Lọ, béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi àti fún àwọn ènìyàn àti fún gbogbo Juda nípa ohun a kọ sínú ìwé yìí a ti . Títóbi ni ìbínú Olúwa ó ń wa nítorí àwọn baba wa tẹ̀̀rọ̀ inú ìwé yìí; wọn ṣe ìbámu pẹ̀gbogbo ohun a kọ níbẹ̀ nípa wa."

14 Hilkiah àlùfáà, Ahikamu àti Akbori Ṣafani pẹ̀Asaiah, lọ ̀dọ̀ wòlíì obìnrin Hulda láti lọ a sọ̀rọ̀, ẹni ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tikfa ọmọ Harhasi alábojútó ibi ìpa aṣọ mọ́ . Ó ń gbé Jerusalẹmu ìdàkejì.

15 Ó fún wọn , "Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli , Sọ fún ọkùnrin ó rán an yín mi, 16 Èyí ni ohun Olúwa : Èmi yóò ibi ibí àti àwọn ènìyàn rẹ ìbámu pẹ̀gbogbo ohun a kọ sínú ìwé ọba Juda ti . 17 Nítorí wọ́n ti kọ̀ sílẹ̀, wọ́n tún sun tùràrí fún ọlọ́run mìíràn. Wọ́n mi bínú nípa gbogbo àwọn òrìṣà wọ́n ti fi ọwọ́ wọn . Ìbínú mi yóò ru ibí yìí, yóò rọlẹ̀.’ 18 Sọ fún ọba Juda ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, Èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run Israẹli nípa ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì ìwọ ti gbọ́. 19 Nítorí ọkàn rẹ rọ̀, ìwọ ti rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa, nígbà ìwọ gbọ́ èyí mo sọ ibí yìí àti àwọn ènìyàn rẹ wọn yóò di ahoro àti ẹni ègún ìwọ fa aṣọ ̀ rẹ ya pẹ̀níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ, ni Olúwa . 20 Nítorí náà èmi yóò jọ ̀dọ̀ àwọn baba à rẹ, a ó sin ́ àlàáfíà. Ojú rẹ yóò gbogbo àwọn ibi èmi yóò ibí yìí.’ "

Bẹ́̀ wọ́n èsì rẹ̀ padà tọ ọba .

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também