Pular para o conteúdo
Publicidade

Mika 3

Bíbá àwọn olórí àti àwọn wòlíì

1 Nígbà náà, ni mo ,

"gbọ́, ̀yin olórí Jakọbu,

̀yin alákòóso ilé Israẹli.

Ǹjẹ́ ̀yin ha ni í gba òdodo .

2 ̀yin ó kórìíra ìre, fẹ́ràn ibi;

̀yin fa awọ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi ya kúrò lára wọn

àti ẹran-ara wọn kúrò egungun wọn;

3 àwọn ó jẹ ẹran-ara àwọn ènìyàn mi,

wọn bọ́ awọ ara wọn kúrò lára wọn.

Wọ́n fọ́ egungun wọn wẹ́wẹ́;

wọn e wẹ́wẹ́ ẹran inú ìkòkò,

ẹran inú agbada?"

4 Nígbà náà ni wọn yóò kígbe Olúwa,

ṣùgbọ́n òun yóò wọn lóhùn.

àkókò náà ni òun yóò fi ojú rẹ̀ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ wọn,

nítorí ibi wọ́n ti ṣe.

5 Báyìí ni Olúwa ,

"ti àwọn Wòlíì

ń ṣi àwọn ènìyàn mi lọ́,

ẹnìkan fún wọn oúnjẹ,

wọn yóò kéde àlàáfíà;

ṣùgbọ́n fi nǹkan wọn ẹnu,

wọn yóò múra ogun i.

6 Nítorí náà òru yóò sórí yín,

̀yin yóò ìran kankan,

òkùnkùn yóò kùn fún yín,

̀yin yóò sọtẹ́lẹ̀.

Oòrùn yóò wọ lórí àwọn wòlíì

ọjọ́ yóò ṣókùnkùn lórí wọn.

7 Ojú yóò ti àwọn wòlíì

àwọn alásọtẹ́lẹ̀ pẹ̀yóò gba ìtìjú.

Gbogbo wọn ni yóò bo ojú wọn,

nítorí ìdáhùn láti ̀dọ̀ Ọlọ́run."

8 Ṣùgbọ́n tèmi,

èmi kún fún agbára pẹ̀̀Olúwa,

láti sọ ìré-òfin-kọjá Jakọbu fún un,

àti láti sọ ̀ṣẹ̀ Israẹli fún un.

9 Gbọ́ ̀yin olórí ilé Jakọbu,

àti ̀yin alákòóso ilé Israẹli,

ó kórìíra òdodo

ó òtítọ́ padà;

10 ó kọ́ Sioni pẹ̀ìtàjẹ̀ sílẹ̀,

àti Jerusalẹmu pẹ̀ìwà búburú.

11 Àwọn olórí rẹ̀ ń ṣe ìdájọ́ nítorí àbẹ̀tẹ́lẹ̀,

àwọn àlùfáà rẹ̀ ń kọ́ni nítorí owó ̀

àwọn wòlíì rẹ̀ pẹ̀ń sọtẹ́lẹ̀ nítorí owó.

Síbẹ̀, wọn gbẹ́kẹ̀Olúwa, wọ́n ,

"Nítòótọ́, Olúwa pẹ̀wa!

Ibi kan yóò wa."

12 Nítorí náà, nítorí tiyín,

ni a ó ṣe ro Sioni oko,

Jerusalẹmu yóò di ebè

àti òkè tẹmpili i ibi gíga igbó.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também