Pular para o conteúdo
Publicidade

Mika 2

Èrò ènìyàn àti ti Ọlọ́run

1 Ègbé ni fún àwọn ń gbèrò àìṣedéédéé

wọ́n ń ṣiṣẹ́ ibi lórí ibùsùn wọn!

Nígbà ojúmọ́ mọ́, wọn yóò gbé e jáde

nítorí ó agbára wọn láti ṣe é.

2 Wọ́n ń ṣe ojúkòkòrò oko, wọ́n fi agbára wọn gbà wọ́n,

àti àwọn ilé, wọ́n gbà wọ́n.

Wọ́n ni ènìyàn àti ilẹ̀ rẹ̀ lára

àní ènìyàn àti ohun ìní rẹ̀.

3 Nítorí náà, Olúwa :

"Èmi ń gbèrò ibi àwọn ìdílé wọ̀nyí,

nínú èyí wọn yóò le è gba ara wọn .

Ìwọ yóò máa rìn ìgbéraga mọ́,

nítorí yóò jẹ́ àkókò ibi.

4 ọjọ́ náà ni ẹnìkan yóò pa òwe kan yín;

wọn yóò pohùnréré ẹkún kíkorò :

kíkó a ti wọn tán;

Olúwa ti pín ohun ìní àwọn ènìyàn mi;

Ó ti un kúrò lọ́dọ̀ mi!

Ó fi oko wa àwọn ọlọ̀tẹ̀ lọ́wọ́.’ "

5 Nítorí náà, ìwọ ẹnìkankan yóò ta okùn nínú ìjọ Olúwa,

yóò pín ilẹ̀ nípa ìbò.

Àwọn wòlíì èké

6 "ṣe sọtẹ́lẹ̀," ni àwọn wòlíì wọn .

"ṣe sọtẹ́lẹ̀ nípa nǹkan wọ̀nyí;

ìtìjú ṣe le wa."

7 Ṣé á sọ ́, ìwọ ilé Jakọbu:

"Ǹjẹ́ ̀Olúwa ha ń bínú ?

Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ ha nìwọ̀nyí?"

"Ǹjẹ́ ̀rọ̀ mi ha ń ṣe rere

fún ẹni ń rìn déédé ?

8 Láìpẹ́ àwọn ènìyàn mi dìde

̀mi.

Ìwọ bọ́ aṣọ ọlọ́rọ̀

kúrò lára àwọn ń kọjá lọ àìléwu,

àwọn ẹni ó padà bọ̀ láti ojú ogun.

9 ̀yin obìnrin àwọn ènìyàn mi

kúrò nínú ilé ayọ̀ wọn,

̀yin ti gba ògo mi,

kúrò lọ́wọ́ àwọn ọmọ wọn láéláé.

10 dìde, máa lọ!

Nítorí èyí í ṣe ibi ìsinmi yín,

nítorí a ti sọ ́ di àìmọ́

yóò pa yín run,

àní ìparun kíkorò.

11 òpùrọ́ àti ẹlẹ́tàn wọ́n ,

Èmi yóò sọtẹ́lẹ̀ fún nípa ̀pọ̀lọpọ̀ wáìnì àti ọtí líle,

òun ni yóò tilẹ̀ ṣe wòlíì àwọn ènìyàn wọ̀nyí!

Ìlérí ìgbàlà

12 "Èmi yóò gbogbo yín jọ, ìwọ Jakọbu;

Èmi yóò gbá ìyókù Israẹli jọ.

Èmi yóò wọn jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ àgùntàn nínú agbo ẹran,

gẹ́gẹ́ ̀wọ́ ẹran nínú agbo wọn,

ibẹ̀ yóò pariwo nítorí ̀pọ̀ ènìyàn.

13 Ẹni ó ń fọ ̀yóò lọ sókè níwájú wọn;

wọn yóò fọ láti ẹnu ibodè, wọn yóò jáde lọ.

Àwọn ọba wọn yóò kọjá lọ níwájú wọn,

Olúwa ni yóò ṣe olórí wọn."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também