Pular para o conteúdo
Publicidade

Mika 1

1 ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Mika ará Moreṣeti àkókò ìjọba Jotamu, Ahasi, àti Hesekiah, àwọn ọba Juda nìwọ̀nyí, ìran ó nípa Samaria àti Jerusalẹmu.

2 gbọ́, gbogbo ̀yin ènìyàn,

fetísílẹ̀, ìwọ ayé àti gbogbo ohun níbẹ̀,

Olúwa Olódùmarè ṣe ẹlẹ́rìí yín,

1.2: 1Ọb 22.28. Olúwa láti inú tẹmpili mímọ́ rẹ̀ .

Ìdájọ́ o lòdì Samaria àti Jerusalẹmu

3 ó! Olúwa ń bọ̀ láti ibùgbé rẹ̀;

yóò sọ̀kalẹ̀, yóò tẹ ibi gíga ayé mọ́lẹ̀.

4 Àwọn òkè ńlá yóò yọ́ lábẹ́ rẹ̀,

àwọn àfonífojì yóò pínyà,

idà níwájú iná,

omi ó ń sàn lọ ni ibi gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́.

5 Nítorí ìré-òfin-kọjá Jakọbu ni gbogbo èyí,

àti nítorí ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli.

ni ìré-òfin-kọjá Jakọbu?

Ǹjẹ́ Samaria ha kọ?

ni àwọn ibi gíga Juda?

Ǹjẹ́ Jerusalẹmu ha kọ?

6 "Nítorí náà, èmi yóò ṣe Samaria òkìtì lórí pápá,

ibi ti à ń fún gbígbin ọgbà àjàrà.

Èmi yóò gbá àwọn òkúta rẹ̀ dànù sínú àfonífojì.

Èmi yóò ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ palẹ̀.

7 Gbogbo àwọn ère fínfín rẹ̀ ni a ó fọ́ wẹ́wẹ́

gbogbo àwọn ̀bùn tẹmpili rẹ̀ ni a ó fi iná sun,

Èmi yóò pa gbogbo àwọn òrìṣà rẹ̀ run.

Nítorí ó ti àwọn ̀bùn rẹ̀ jọ láti inú owó èrè panṣágà,

gẹ́gẹ́ owó èrè panṣágà, wọn yóò tún padà owó iṣẹ́ panṣágà."

Ẹkún òun ọfọ̀

8 Nítorí èyí, èmi yóò sọkún,

èmi yóò pohùnréré ẹkún:

èmi yóò máa lọ ẹsẹ̀ lásán àti ìhòhò.

Èmi yóò akátá,

èmi yóò máa dárò àwọn ọmọ ògòǹgò.

9 Nítorí ọgbẹ́ rẹ̀ jẹ́ aláìlèwòtán;

ó ti Juda.

Ó ti ẹnu-bodè àwọn ènìyàn mi,

àní Jerusalẹmu.

10 ṣe sọ Gati

ṣe sọkún rárá.

ilẹ̀ Beti-Ofra

mo ara mi nínú eruku.

11 kọjá lọ ni ìhòhò àti ni ìtìjú,

ìwọ ó ń gbé ni Ṣafiri.

Àwọn ó ń gbé ni Saanani

yóò jáde .

Beti-Eseli nínú ̀fọ̀;

a ó gba ààbò rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ yin.

12 Nítorí àwọn ó ń gbé ni Marati ń retí ìre,

ṣùgbọ́n ibi sọ̀kalẹ̀ ti ̀dọ̀ Olúwa ẹnu-bodè Jerusalẹmu.

13 Ìwọ olùgbé Lakiṣi,

kẹ̀kẹ́ mọ́ ẹranko ó yára.

Òun ni ìbẹ̀rẹ̀ ̀ṣẹ̀

àwọn ọmọbìnrin Sioni,

nítorí a àìṣedéédéé Israẹli nínú rẹ̀.

14 Nítorí náà ni ìwọ ó ṣe fi ìwé ìkọ̀sílẹ̀

fún Moreṣeti Gati.

Àwọn ilé Aksibu yóò jẹ́ ẹlẹ́tàn àwọn ọba Israẹli.

15 Èmi yóò àrólé kan sórí rẹ ìwọ olùgbé Meraṣa.

Ẹni ó jẹ́ ògo Israẹli

yóò Adullamu.

16 irun orí rẹ nínú ̀fọ̀

nítorí àwọn ọmọ rẹ aláìlágbára,

sọ ra rẹ̀ di apárí ẹyẹ igún,

nítorí wọn yóò kúrò lọ́dọ̀ rẹ lọ ìgbèkùn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também