Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Ọba 13

Ènìyàn Ọlọ́run kan láti Juda

1 kíyèsi i, ènìyàn Ọlọ́run kan láti Juda Beteli nípa ̀rọ̀ Olúwa, Jeroboamu ti dúró lẹ́bàá a pẹpẹ láti fi tùràrí jóná. 2 Ó kígbe pẹpẹ náà nípa ̀rọ̀ Olúwa , "Pẹpẹ! Pẹpẹ! Báyìí ni Olúwa : A ó ọmọkùnrin kan orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Josiah ilé Dafidi. Lórí rẹ ni yóò fi àwọn àlùfáà ibi gíga wọ̀n-ọn-nì ń fi tùràrí lórí rẹ̀ ẹbọ, a ó sun egungun ènìyàn lórí rẹ.’ " 3 ọjọ́ kan náà ènìyàn Ọlọ́run fún wọn àmì kan , "Èyí ni àmì Olúwa ti kéde: kíyèsi i, pẹpẹ náà yóò ya, eérú ń bẹ lórí rẹ̀ yóò dànù."

4 Nígbà Jeroboamu ọba gbọ́ ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run, ó kígbe pẹpẹ náà Beteli, ó na ọwọ́ rẹ̀ jáde nínú pẹpẹ, ó , "un!" ṣùgbọ́n ọwọ́ rẹ̀ ó i kákò, bẹ́̀ ni le á padà mọ́. 5 Lẹ́sẹ̀kan náà, pẹpẹ ya, eérú náà dànù kúrò lórí pẹpẹ náà gẹ́gẹ́ àmì ènìyàn Ọlọ́run ti fi fún un nípa ̀rọ̀ Olúwa.

6 Nígbà náà ọba fún ènìyàn Ọlọ́run náà , "Bẹ̀bẹ̀ pẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ, o gbàdúrà fún mi ọwọ́ mi padà bọ̀ sípò." Bẹ́̀ ni ènìyàn Ọlọ́run náà bẹ̀bẹ̀ lọ́dọ̀ Olúwa, ọwọ́ ọba padà bọ̀ sípò, ó padà ó ti tẹ́lẹ̀.

7 Ọba fún ènìyàn Ọlọ́run náà , "mi lọ ilé, o nǹkan jẹ, èmi yóò fi ̀bùn fún ."

8 Ṣùgbọ́n ènìyàn Ọlọ́run náà ọba lóhùn , "ìwọ yóò tilẹ̀ fún mi ìdajì ìní rẹ, èmi yóò lọ pẹ̀rẹ tàbí èmi jẹ oúnjẹ tàbí mu omi ibí yìí. 9 Nítorí a ti pa á láṣẹ fún mi nípa ̀rọ̀ Olúwa , Ìwọ gbọdọ̀ jẹ oúnjẹ tàbí mu omi tàbí padà ̀náà o gbà .’ " 10 Bẹ́̀ ni ó gba ̀mìíràn, padà gba ̀ó gbà Beteli.

11 Wòlíì àgbà kan ń gbé Beteli, ẹni àwọn ọmọ rẹ̀ , ó ròyìn gbogbo ohun ènìyàn Ọlọ́run náà ti ṣe Beteli ọjọ́ náà fún un. Wọ́n tún sọ fún baba wọn ohun ó sọ fún ọba. 12 Baba wọn béèrè lọ́wọ́ wọn , "̀wo ni ó gbà?" Àwọn ọmọ rẹ̀ fi ̀ènìyàn Ọlọ́run láti Juda gbà hàn án. 13 Nígbà náà ni ó fún àwọn ọmọ rẹ̀ , "di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gàárì fún mi." Nígbà wọ́n ti di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gàárì fún un tán, ó gùn ún. 14 Ó tẹ̀ènìyàn Ọlọ́run náà lẹ́yìn. Ó i ó jókòó lábẹ́ igi óákù kan, ó fún un , "Ǹjẹ́ ìwọ ni ènìyàn Ọlọ́run ó ti Juda ?"

Ó a lóhùn , "Èmi ni."

15 Nígbà náà ni wòlíì náà fún un , "mi lọ ilé, o jẹun."

16 Ènìyàn Ọlọ́run náà , "Èmi le padà sẹ́yìn tàbí lọ ilé, tàbí èmi ó jẹ oúnjẹ tàbí mu omi pẹ̀rẹ níhìn-ín. 17 A ti sọ fún mi nípa ̀rọ̀ Olúwa , Ìwọ gbọdọ̀ jẹ oúnjẹ tàbí mu omi níhìn-ín tàbí o padà lọ nípa ̀ìwọ .’ "

18 Wòlíì àgbà náà fún un , "Wòlíì ni èmi náà pẹ̀, gẹ́gẹ́ ìwọ. Angẹli sọ fún mi nípa ̀rọ̀ Olúwa , un padà ilé rẹ, ó jẹ oúnjẹ àti ó mu omi.’ " (Ṣùgbọ́n ó purọ́ fún un ni.) 19 Bẹ́̀ ni ènìyàn Ọlọ́run náà padà pẹ̀rẹ̀, ó jẹ oúnjẹ ó mu omi ilé rẹ̀.

20 wọ́n ti jókòó ti tábìlì, ̀rọ̀ Olúwa tọ wòlíì ó un padà ; 21 Ó kígbe ènìyàn Ọlọ́run ó ti Juda , "Báyìí ni Olúwa : Ìwọ ti ba ̀rọ̀ Olúwa jẹ́, ìwọ pa àṣẹ Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún mọ́. 22 Ìwọ padà, ìwọ ti jẹ oúnjẹ, ìwọ ti mu omi níbi ó ti sọ fún ìwọ ó ṣe jẹ oúnjẹ tàbí mu omi. Nítorí náà, a yóò sin òkú rẹ sínú ibojì àwọn baba rẹ.’ "

23 Nígbà ènìyàn Ọlọ́run ti jẹun tán àti mu omi tan, wòlíì ó ti u padà di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gàárì fún un. 24 ó ti ń lọ ̀rẹ̀, kìnnìún kan pàdé rẹ̀ ̀, ó pa á, a gbé òkú rẹ̀ sọ ojú ̀, pẹ̀kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti kìnnìún ó dúró í lẹ́gbẹ̀́. 25 Àwọn ènìyàn ó ń kọjá ó gbé òkú náà sọ ojú ̀, kìnnìún náà dúró ti òkú náà; wọ́n , wọ́n sọ ́ ìlú wòlíì àgbà náà ń gbé.

26 Nígbà wòlíì ó un padà láti ̀rẹ̀ gbọ́ èyí, ó , "Ènìyàn Ọlọ́run náà ni ó ba ̀rọ̀ Olúwa jẹ́. Olúwa ti fi kìnnìún lọ́wọ́, ó á ya, ó pa á, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa ó ti kìlọ̀ fún un."

27 Wòlíì náà fún àwọn ọmọ rẹ̀ , "di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ gàárì fún mi," wọ́n ṣe bẹ́̀. 28 Nígbà náà ni ó jáde lọ, ó òkú náà a gbé sọ ojú ̀, pẹ̀kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti kìnnìún ó dúró lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀. Kìnnìún náà jẹ òkú náà, tàbí fa kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà ya. 29 Nígbà náà ni wòlíì náà gbé òkú ènìyàn Ọlọ́run náà, ó gbé e orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó gbé e padà ìlú ara rẹ̀ láti ṣọ̀fọ̀ fún un àti láti sin ín. 30 Nígbà náà ni ó gbé òkú náà sínú ibojì ara rẹ̀, wọ́n ṣọ̀fọ̀ lórí rẹ̀, wọ́n , "Ó ṣe, arákùnrin mi!"

31 Lẹ́yìn ìgbà ó ti sìnkú rẹ̀ tán, ó fún àwọn ọmọ rẹ̀ , "Nígbà mo , sin ibojì níbi a sin ènìyàn Ọlọ́run ; tẹ́ egungun mi lẹ́bàá egungun rẹ̀. 32 Nítorí iṣẹ́ ó jẹ́ nípa ̀rọ̀ Olúwa pẹpẹ ó Beteli àti gbogbo ojúbọ lórí ibi gíga ń bẹ àwọn ìlú Samaria yóò ìmúṣẹ dájúdájú."

33 Lẹ́yìn nǹkan yìí, Jeroboamu padà kúrò nínú ̀búburú rẹ̀, ṣùgbọ́n ó tún yan àwọn àlùfáà i fún àwọn ibi gíga nínú gbogbo àwọn ènìyàn. Ẹnikẹ́ni ó fẹ́ di àlùfáà, a á sọ́tọ̀ fún ibi gíga wọ̀nyí. 34 Èyí ni ̀ṣẹ̀ ilé Jeroboamu, èyí ó yọrí ìṣubú rẹ̀, a pa á run kúrò lórí ilẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também