Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 10

Saulu gba ̀ara rẹ̀

1 10.1-12: 1Sa 31.1-13. Nísinsin yìí, àwọn ará Filistini dojú ìjà kọ Israẹli, àwọn ará Israẹli sálọ kúrò níwájú wọn, a pa ̀pọ̀ wọn orí òkè Gilboa. 2 Àwọn ará Filistini lépa Saulu gidigidi àti àwọn ọmọ rẹ̀. Wọ́n pa àwọn ọmọ rẹ̀. Jonatani, Abinadabu àti Malikiṣua. 3 Ogun náà gbóná janjan fún Saulu, nígbà àwọn tafàtafà e , wọ́n ṣá a lọ́gbẹ́.

4 Saulu sọ fún ẹni ó gbé ìhámọ́ra rẹ̀ , "Fa idà rẹ yọ, o fi gún mi, àwọn aláìkọlà wọ̀nyí láti mi."

Ṣùgbọ́n ẹni ó ń gbé ìhámọ́ra rẹ̀ ń bẹ̀, le ṣe é, bẹ́̀ ni Saulu idà tirẹ̀ ó ṣubú e. 5 Nígbà agbé-ìhámọ́ra Saulu ti , òhun pẹ̀ṣubú lórí idà tirẹ̀, ó . 6 Bẹ́̀ ni Saulu àti ọmọ rẹ̀ mẹ́tẹ̀̀ta , gbogbo ilé rẹ̀ ṣọ̀kan, lọ́jọ́ kan náà.

7 Nígbà gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ó pẹ̀tẹ́lẹ̀ àwọn ọmọ-ogun ti sálọ àti Saulu àti àwọn ọmọ rẹ̀ ti wọ́n kọ àwọn ìlú wọn sílẹ̀, wọ́n sálọ. Àwọn ará Filistini , wọ́n jókòó nínú wọn.

8 ọjọ́ kejì, nígbà àwọn ará Filistini láti òkú, wọ́n Saulu àti àwọn ọmọ rẹ̀ wọ́n ṣubú sórí òkè Gilboa. 9 Wọ́n bọ́ aṣọ, wọ́n gbé orí rẹ̀ àti ìhámọ́ra rẹ̀, wọ́n rán ìránṣẹ́ lọ káàkiri ilẹ̀ àwọn ará Filistini láti kéde ìròyìn náà láàrín àwọn òrìṣà wọn àti àwọn ènìyàn wọn. 10 Wọ́n gbé ìhámọ́ra rẹ̀ inú ilé wọ́n kọ́ fún òrìṣà wọn, wọ́n fi orí rẹ̀ kọ́ inú ilé Dagoni.

11 Nígbà gbogbo àwọn olùgbé JabesiGileadi gbọ́ gbogbo ohun àwọn ará Filistini ṣe fún Saulu, 12 gbogbo àwọn akọni ọkùnrin wọn lọ láti àwọn ará Saulu àti àwọn ọmọ rẹ̀, wọ́n wọn Jabesi. Nígbà náà, wọ́n sin egungun wọn sábẹ́ igi óákù Jabesi, wọ́n gbààwẹ̀ fún ọjọ́ méje.

13 Saulu nítorí ṣe òtítọ́ Olúwa, pa ̀rọ̀ Olúwa mọ́ pẹ̀, ó tọ abókùúsọ̀rọ̀ lọ fún ìtọ́sọ́. 14 béèrè lọ́wọ́ Olúwa, bẹ́̀ ni Olúwa pa á, Ó ìjọba náà padà sọ́dọ̀ Dafidi ọmọ Jese.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também