Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Kronika 2

Àwọn ọmọ Israẹli

1 2.1-2: Gẹ 35.23-26. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni, 2 Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.

Juda

Àwọn ọmọ Hesroni

3 2.3-4: Gẹ 38.3-7,29-30; Nu 26.19,20. Àwọn ọmọ Juda:

Eri, Onani àti Ṣela, àwọn mẹ́tẹ̀̀ta wọ̀nyí ni wọ́n fún un láti ̀dọ̀ arábìnrin Kenaani, ọmọbìnrin Ṣua.

Eri àkọ́Juda, ó burú ojú Olúwa, bẹ́̀ ni Olúwa pa á.

4 Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó Peresi àti Sera ọmọ márùn-ún àpapọ̀.

5 2.5: Gẹ 46.12; Gẹ 26.21. Àwọn ọmọ Peresi:

Hesroni àti Hamulu.

6 Àwọn ọmọ Sera:

Simri, Etani, Hemani, Kalkoli àti Dara, gbogbo wọn jẹ́ márùn-ún.

7 Àwọn ọmọ Karmi:

Akani, ẹni ó ìyọnu sórí Israẹli nípa ̀ṣẹ̀ ìfibú lórí mímú ohun ìyàsọ́tọ̀.

8 Àwọn ọmọ Etani:

Asariah.

9 Àwọn ọmọ a fún Hesroni ni:

Jerahmeeli, Ramu àti Kalebu.

Láti ̀dọ̀ Ramu ọmọ Hesroni

10 Ramu ni baba Amminadabu,

àti Amminadabu baba Nahiṣoni olórí àwọn ènìyàn Juda.

11 Nahiṣoni ni baba Salmoni,

Salmoni ni baba Boasi,

12 Boasi baba Obedi

àti Obedi baba Jese.

13 Jese ni baba

Eliabu àkọ́rẹ̀; ọmọ ẹlẹ́̀kejì ni Abinadabu,

ẹlẹ́̀kẹta ni Ṣimea, 14 ẹlẹ́̀kẹrin Netaneli,

ẹlẹ́̀karùnún Raddai, 15 ẹlẹ́̀kẹfà Osemu

àti ẹlẹ́̀keje Dafidi.

16 Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili.

Àwọn ọmọ mẹ́ta Seruiah ni Abiṣai, Joabu àti Asaheli.

17 Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni baba rẹ̀ jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.

Kalebu ọmọ Hesroni

18 Kalebu ọmọ Hesroni ọmọ láti ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀:

Jeṣeri, Ṣobabu àti Ardoni.

19 Nígbà Asuba , Kalebu fẹ́ Efrata aya, ẹni ó Huri fún un.

20 Huri ni baba Uri, Uri jẹ́ baba Besaleli.

21 Nígbà ó , Hesroni dùbúlẹ̀ pẹ̀ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó ti fẹ́ aya láti ìgbà ó ti ẹni ọgọ́ta ọdún) ó Segubu.

22 Segubu jẹ́ baba Jairi, ẹni ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ilẹ̀ Gileadi.

23 (Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀gbogbo agbègbè rẹ̀ wọn tẹ̀jẹ́ ọgọ́ta ìlú.)

Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Makiri baba Gileadi.

24 Lẹ́yìn Hesroni ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni Aṣihuri baba Tekoa fún un.

Jerahmeeli ọmọ Hesroni

25 Ọmọ Jerahmeeli àkọ́Hesroni:

Ramu ọmọ àkọ́rẹ̀ Buna, Oreni, Osemu àti Ahijah. 26 Jerahmeeli ìyàwó mìíràn, ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó jẹ́ ìyá fún Onamu.

27 Àwọn ọmọ Ramu àkọ́Jerahmeeli:

Maasi, Jamini àti Ekeri.

28 Àwọn ọmọ Onamu:

Ṣammai àti Jada.

Àwọn ọmọ Ṣammai:

Nadabu àti Abiṣuri. 29 Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni ó Ahbani àti Molidi.

30 Àwọn ọmọ Nadabu

Seledi àti Appaimu. Seledi láìsí ọmọ.

31 Àwọn ọmọ Appaimu:

Iṣi, ẹni ó jẹ́ baba fún Ṣeṣani. Ṣeṣani jẹ́ baba fún Ahlai.

32 Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai:

Jeteri àti Jonatani. Jeteri láìní ọmọ.

33 Àwọn ọmọ Jonatani:

Peleti àti Sasa.

Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Jerahmeeli.

34 Ṣeṣani ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó .

Ó ìránṣẹ́ ará Ejibiti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jariha. 35 Ṣeṣani fi ọmọ obìnrin rẹ̀ aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó ọmọ fún orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.

36 Attai jẹ́ baba fún Natani,

Natani jẹ́ baba fún Sabadi,

37 Sabadi ni baba Eflali,

Eflali jẹ́ baba Obedi,

38 Obedi ni baba Jehu,

Jehu ni baba Asariah,

39 Asariah ni baba Helesi,

Helesi ni baba Eleasa,

40 Eleasa ni baba Sismai,

Sismai ni baba Ṣallumu,

41 Ṣallumu ni baba Jekamiah,

Jekamiah ni baba Eliṣama.

Ìdílé Kalebu

42 Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli:

Meṣa àkọ́rẹ̀, ẹni ó jẹ́ baba fún Sifi,

àti àwọn ọmọ rẹ̀ Meraṣa, ẹni ó jẹ́ baba fún Hebroni.

43 Àwọn ọmọ Hebroni:

Kora, Tapua, Rekemu, àti Ṣema.

44 Ṣema ni baba Rahamu,

Rahamu jẹ́ baba fún Jorkeamu.

Rekemu ni baba Ṣammai.

45 Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni,

Maoni ni baba Beti-Suri.

46 Efani obìnrin Kalebu ni ìyá

Harani, Mosa àti Gasesi,

Harani ni baba Gasesi.

47 Àwọn ọmọ Jahdai:

Regemu, Jotamu, Geṣani, Peleti, Efani àti Ṣaafu.

48 Maaka obìnrin Kalebu ni ìyá

Seberi àti Tirhana.

49 Ó Ṣaafu baba Madmana,

Ṣefa baba Makbena àti baba Gibeah,

ọmọbìnrin Kalebu ni Aksa.

50 Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu.

Àwọn ọmọ Huri, àkọ́Efrata:

Ṣobali baba Kiriati-Jearimu. 51 Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.

52 Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni:

Haroe, ìdajì àwọn ará Manaheti. 53 Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti .

54 Àwọn ọmọ Salma:

Bẹtilẹhẹmu, àti àwọn ará Netofa, Atrotu Beti-Joabu, ìdajì àwọn ará Manahati, àti ará Sori, 55 àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀, ẹni ń gbé Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni ó láti ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também