Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 9

Ìwà àrékérekè Gibeoni

1 Nísinsin yìí, nígbà gbogbo ọba ìwọ̀-oòrùn Jordani gbọ́ nípa nǹkan wọ̀nyí, àwọn náà ó orí òkè àti àwọn ó ẹsẹ̀ òkè, àti gbogbo àwọn ó agbègbè Òkun Ńlá títí ó fi Lebanoni (àwọn ọba Hiti, Amori, Kenaani, Peresi, Hifi àti Jebusi) 2 wọ́n ara wọn jọ láti Joṣua àti Israẹli jagun.

3 Ṣùgbọ́n nígbà àwọn ènìyàn Gibeoni gbọ́ ohun Joṣua ṣe Jeriko àti Ai, 4 wọ́n ọgbọ́n ̀tàn. Wọ́n lọ gẹ́gẹ́ aṣojú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn kún fún ẹrù a fi àwọn àpò ti gbó , àti àwọn awọ ọtí wáìnì ti gbó a tún rán. 5 Àwọn ọkùnrin náà wọ bàtà àti aṣọ ó ti gbó. Gbogbo oúnjẹ wọ́n pèsè fún ara wọn bu. 6 Wọ́n tọ Joṣua lọ ibùdó Gilgali, wọ́n sọ fún òun àti àwọn ọkùnrin Israẹli , "Ìlú òkèrè àwọn ti , ṣe àdéhùn àlàáfíà pẹ̀wa."

7 Àwọn ọkùnrin Israẹli sọ fún àwọn ará Hifi , "Ṣùgbọ́n bóyá tòsí wa ni ń gbé. Báwo ni a ó ṣe ṣe àdéhùn pẹ̀yín?"

8 "Ìránṣẹ́ rẹ àwa í ṣe." Wọ́n sọ fún Joṣua.

Ṣùgbọ́n Joṣua béèrè, "Ta ni yín àti níbo ni ̀yin ti ?"

9 Wọ́n dáhùn , "ilẹ̀ òkèèrè àwọn ìránṣẹ́ rẹ , nítorí orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ. Nítorí àwa ti gbọ́ òkìkí rẹ àti ohun gbogbo ó ti ṣe Ejibiti, 10 àti ohun gbogbo ó ti ṣe ọba àwọn Amori méjèèje ń bẹ òkè Jordani, Sihoni ọba Heṣboni, àti Ogu ọba Baṣani, wọ́n jẹ ọba Aṣtarotu. 11 Àwọn àgbàgbà wa àti gbogbo àwọn ń gbé ìlú wa sọ fún wa , oúnjẹ lọ́wọ́ fún ìrìnàjò yín, lọ pàdé wọn, sọ fún wọn , "Àwa ni ìránṣẹ́ yín, àdéhùn pẹ̀wa." 12 Gbígbóná a oúnjẹ wa , nígbà a í ilé ọjọ́ à ń bọ̀ sọ́dọ̀ yín. Ṣùgbọ́n ó ó ṣe gbẹ àti ó ṣe bu nísinsin yìí. 13 Àti ìgò wáìnì wọ̀nyí, àwa rọ kún tuntun ni, ṣùgbọ́n ó wọ́n ti sán. Aṣọ àti bàtà wa ni ó ti gbó nítorí ìrìnàjò ̀jíjìn."

14 Àwọn ọkùnrin Israẹli yẹ oúnjẹ wọn , wọn wádìí ọwọ́ Olúwa. 15 Nígbà náà ni Joṣua ṣe àdéhùn àlàáfíà pẹ̀wọn láti wọn , àti àwọn olórí ìjọ ènìyàn fi ọwọ́ àdéhùn náà nípa ṣíṣe ìbúra.

16 ̀yìn ọjọ́ mẹ́ta wọ́n ti ṣe àdéhùn pẹ̀àwọn ará Gibeoni, àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ aládùúgbò wọn ni wọ́n, ń gbé tòsí wọn. 17 Bẹ́̀ àwọn ọmọ Israẹli jáde, wọ́n ìlú wọn ọjọ́ kẹta: Gibeoni, Kefira, Beeroti àti Kiriati-Jearimu. 18 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli si kọlù wọ́n, nítorí àwọn àgbàgbà ìjọ ènìyàn ti búra fún wọn orúkọ Olúwa Ọlọ́run Israẹli.

Gbogbo ènìyàn kùn àwọn àgbàgbà náà, 19 ṣùgbọ́n gbogbo àwọn olórí dáhùn , "Àwa ti búra fún wọn orúkọ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, a fọwọ́ kàn wọ́n nísinsin yìí. 20 Èyí àwa yóò ṣe wọn, àwa yóò wọn , ìbínú ó ba à sórí wa, nítorí ìbúra a búra fún wọn." 21 Wọ́n tẹ̀síwájú, "wọn , ṣùgbọ́n jẹ́ wọn jẹ́ gégigégi àti apọnmi fún gbogbo ìlú." Àwọn àgbàgbà náà ìlérí wọn ṣẹ fún wọn.

22 Nígbà náà ni Joṣua pe àwọn ọmọ Gibeoni jọ , "Èéṣe ̀yin fi tàn pe, Àwa gbé ibi ó jìnnà yín,nígbà ó jẹ́ tòsí wa ̀yin ń gbé? 23 Nísinsin yìí, ̀yin di ẹni ègún, ̀yin kúrò gégigégi àti apọnmi fún ilé Ọlọ́run mi."

24 Wọ́n Joṣua lóhùn , "Nítorí a sọ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ dájúṣáká Olúwa Ọlọ́run rẹ ti pàṣẹ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ̀, láti fún yín gbogbo ilẹ̀ náà, ó pa gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà run kúrò iwájú yín. Nítorí náà, àwa bẹ̀̀wa nítorí yín, èyí ni ìdí a fi ṣe bẹ́̀. 25 Nísinsin yìí, àwa ọwọ́ yín. Ohunkóhun ó yẹ ó si tọ́ lójú yín fi ṣe."

26 Bẹ́̀ Joṣua gbà wọ́n kúrò ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli. Wọn pa wọ́n. 27 ọjọ́ náà ni ó sọ àwọn Gibeoni di aṣẹ́gi àti apọnmi fún àwọn ará ìlú àti fún pẹpẹ Olúwa ibi Olúwa yóò yàn. Báyìí ni wọ́n títí di òní yìí.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também