Pular para o conteúdo
Publicidade

Joṣua 13

Ilẹ̀ ó láti gbà

1 Nígbà Joṣua darúgbó ọjọ́ orí rẹ̀ pọ̀ jọjọ, Olúwa sọ fún un , "Ìwọ ti darúgbó púpọ̀, bẹ́̀ ni ilẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ fún yín láti gbà.

2 "Èyí ni ilẹ̀ ó :

"gbogbo àwọn agbègbè àwọn Filistini, àti ti ara Geṣuri: 3 láti odò Ṣihori ìlà-oòrùn Ejibiti agbègbè Ekroni ìhà àríwá, gbogbo rẹ̀ ni a kún Kenaani (agbègbè ìjòyè Filistini márùn-ún Gasa, Aṣdodu, Aṣkeloni, Gitti àti Ekroni;

ti àwọn ará Affimu); 4 láti gúúsù;

gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, láti Arah ti àwọn ará Sidoni títí ó fi Afeki, agbègbè àwọn ará Amori,

5 àti ilẹ̀ àwọn ará Gebali;

àti gbogbo àwọn Lebanoni ìlà-oòrùn, láti Baali-Gadi ìsàlẹ̀ òkè Hermoni Lebo-Hamati.

6 "ti gbogbo àwọn olùgbé agbègbè òkè, láti Lebanoni Misrefoti-Maimu, àní, gbogbo àwọn ará Sidoni, èmi fúnra mi yóò wọn jáde iwájú àwọn ará Israẹli. o ri dájú o pín ilẹ̀ fún Israẹli ilẹ̀ ìní, gẹ́gẹ́ mo ṣe fi àṣẹ fún , 7 pín ilẹ̀ yìí ilẹ̀ ìní fún àwọn ̀mẹ́sàn-án àti ìdajì ̀Manase."

Pínpín ilẹ̀ ìhà ìlà-oòrùn Jordani

8 Àwọn ìdajì ̀Manase ó , àti àwọn Reubeni àti àwọn Gadi ti gba ilẹ̀ ìní, Mose ti fún wọn ìhà ìlà-oòrùn Jordani Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi fún wọn.

9 Ó lọ títí láti Aroeri ń bẹ létí àfonífojì Arnoni, àti láti ìlú náà ń bẹ àárín àfonífojì náà, àti pẹ̀gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ Medeba títí Diboni. 10 Gbogbo ìlú Sihoni ọba àwọn Amori, ó ṣe àkóso Heṣboni, títí ààlà àwọn ará Ammoni.

11 Àti Gileadi, agbègbè àwọn ènìyàn Geṣuri àti Maakati, gbogbo òkè Hermoni àti gbogbo Baṣani títí Saleka, 12 ìyẹn, gbogbo ilẹ̀ ọba Ogu Baṣani, ó jẹ ọba Aṣtarotu àti Edrei, ẹni ó nínú àwọn Refaimu ìyókù. Mose ti ṣẹ́gun wọn, ó ti gba ilẹ̀ wọn. 13 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli àwọn ará Geṣuri àti Maakati jáde, bẹ́̀ ni wọ́n ń gbé àárín àwọn ará Israẹli títí di òní yìí.

14 Ṣùgbọ́n àwọn ̀Lefi ni fi ogún kankan fún, níwọ̀n ìgbà ó ti jẹ́ ọrẹ àfinásun Olúwa Ọlọ́run Israẹli ni ogún tiwọn, gẹ́gẹ́ o ti ṣèlérí fún wọn.

15 Èyí ni Mose fi fún ̀Reubeni ni agbo ilé agbo ilé,

16 láti agbègbè Aroeri etí Arnoni Jọ́́àti láti ìlú ń bẹ láàrín Jọ́́, àti gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ ìkọjá Medeba 17 Heṣboni àti gbogbo ìlú rẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀, pẹ̀Diboni, Bamoti Baali, Beti-Baali-Mioni, 18 Jahisa, Kedemoti, Mefaati, 19 Kiriataimu, Sibma, Sereti Ṣahari lórí òkè àfonífojì. 20 Beti-Peori, gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Pisga, àti Beti-Jeṣimoti 21 gbogbo ìlú ó pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti gbogbo agbègbè Sihoni ọba Amori, ó ṣe àkóso Heṣboni. Mose ti ṣẹ́gun rẹ̀ àti àwọn ọmọ ìjòyè Midiani, Efi, Rekemu, Suri, Huri àti Reba, àwọn ọmọ ọba pawọ́pọ̀ pẹ̀Sihoni ó gbé ilẹ̀ náà. 22 àfikún àwọn a pa ogun, àwọn ọmọ Israẹli fi idà pa Balaamu ọmọ Beori alásọtẹ́lẹ̀.

23 Ààlà àwọn ọmọ Reubeni ni etí odò Jordani. Àwọn ìlú wọ̀nyí àti abúlé rẹ̀ ni ilẹ̀ ìní àwọn ọmọ Reubeni agbo ilé agbo ilé.

24 Èyí ni ohun Mose ti fi fún ̀Gadi, agbo ilé agbo ilé.

25 Agbègbè ìlú Jaseri, gbogbo ìlú Gileadi àti ìdajì orílẹ̀-èdè àwọn ọmọ ará Ammoni títí Aroeri, ̀Rabba; 26 àti láti Heṣboni lọ Ramati-Mispa àti Betonimu, àti láti Mahanaimu agbègbè ìlú Debiri, 27 àti àfonífojì Beti-Haramu, Beti-Nimra, Sukkoti àti Safoni pẹ̀ìyókù agbègbè ilẹ̀ Sihoni ọba Heṣboni (ìhà ìlà-oòrùn Jordani, agbègbè rẹ̀ títí òpin Òkun Kinnereti).

28 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti abúlé rẹ̀ jẹ́ ogún àwọn ọmọ Gadi, agbo ilé agbo ilé.

29 Èyí ni ohun Mose ti fi fún ìdajì ̀Manase, èyí ni , fún ìdajì ìdílé irú-ọmọ Manase, agbo ilé agbo ilé.

30 Ilẹ̀ náà fẹ̀ Mahanaimu àti gbogbo Baṣani, gbogbo agbègbè ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani, èyí í ṣe ibùgbé Jairi Baṣani, ọgọ́ta ìlú, 31 ìdajì Gileadi, àti Aṣtarotu àti Edrei (àwọn ìlú ọba Ogu Baṣani).

Èyí ni fún irú àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase fún ààbọ̀ àwọn ọmọ Makiri, agbo ilé agbo ilé.

32 Èyí ni ogún Mose fi fún wọn nígbà ó pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ìhà kejì Jordani ìlà-oòrùn Jeriko. 33 Ṣùgbọ́n fún ̀Lefi, Mose fi ogún fún un; Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ogún wọn, gẹ́gẹ́ ó ti ṣe ìlérí fún wọn.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também