Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 7

Àmì ti Emmanueli

1 Nígbà Ahasi ọmọ Jotamu ọmọ Ussiah jẹ́ ọba Juda, ọba Resini ti Aramu àti Peka ọmọ Remaliah ọba Israẹli gòkè láti Jerusalẹmu , ṣùgbọ́n wọn le è borí i rẹ̀.

2 Báyìí, a sọ fún ilé Dafidi , "Aramu ti lẹ̀àpò pọ̀ mọ́ Efraimu"; fún ìdí èyí, ọkàn Ahasi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ wárìrì gẹ́gẹ́ igi oko ṣe ń wárìrì níwájú afẹ́fẹ́.

3 Lẹ́yìn èyí, Olúwa sọ fún Isaiah , "Jáde, ìwọ àti ̀dọ́mọkùnrin rẹ Ṣeari-Jaṣubu láti pàdé Ahasi ìpẹ̀kun ìṣàn omi ti adágún òkè, òpópó ̀ó lọ pápá Alágbàfọ̀. 4 Sọ fún un, Ṣọ́ra à rẹ, fi ọkàn balẹ̀, o ṣe bẹ̀. ṣe ba ọkàn jẹ́ nítorí kùkùté igi ìdáná méjèèjì yìí, nítorí ìbínú gbígbóná Resini àti Aramu àti ti ọmọ Remaliah. 5 Aramu, Efraimu àti Remaliah ti dìtẹ̀ ìparun rẹ, wọ́n , 6 "Jẹ́ a kọlu Juda; jẹ́ a á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, a pín in láàrín ara wa, a fi ọmọ Tabeli jẹ ọba lórí i rẹ̀." 7 Síbẹ̀ èyí ni ohun Olúwa Olódùmarè :

" Èyí wáyé

èyí le ṣẹlẹ̀,

8 nítorí Damasku ni orí Aramu,

orí Damasku ni Resini.

Láàrín ọdún márùnlélọ́gọ́ta

Efraimu yóò ti fọ́ yóò le jẹ́ ènìyàn mọ́.

9 Orí Efraimu ni Samaria,

orí Samaria ni ọmọ Remaliah.

̀yin yóò gbàgbọ́,

lóòtítọ́, a yóò fi ìdí yín múlẹ̀.’ "

10 Bákan náà Olúwa tún Ahasi sọ̀rọ̀, 11 "Béèrè fún àmì lọ́wọ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, bóyá ̀gbun ó jùlọ tàbí àwọn òkè ó ga jùlọ."

12 Ṣùgbọ́n Ahasi sọ , "Èmi yóò béèrè; Èmi dán Olúwa ."

13 Lẹ́yìn náà Isaiah sọ , "Gbọ́ ìsinsin yìí, ìwọ ilé Dafidi, ha tọ́ láti tán ènìyàn sùúrù, ìwọ yóò ha tan Ọlọ́run sùúrù ? 14 7.14: Mt 1.23.Nítorí náà, Olúwa fúnra ara rẹ̀ ni yóò fún àmì kan. Wúńdíá kan yóò lóyún, yóò ọmọkùnrin kan, yóò pe orúkọ rẹ̀ Emmanueli. 15 Òun yóò jẹ wàrà àti oyin nígbà ó ìmọ̀ láti kọ ̀bi àti láti yan rere. 16 Ṣùgbọ́n ̀dọ́mọkùnrin náà mọ a ti ń kọ ̀bi àti láti yan rere, ilẹ̀ àwọn ọba méjèèjì ń ́ lẹ́wọ̀nyí yóò ti di ahoro. 17 Olúwa yóò àsìkò mìíràn fún àti àwọn ènìyàn rẹ àti lórí ilé baba rẹ irú èyí láti ìgbà Efraimu ti kúrò Juda, yóò ọba Asiria ."

18 ọjọ́ náà ni Olúwa yóò súfèé pe àwọn eṣinṣin láti àwọn odò jìnnà Ejibiti , àti fún àwọn oyin láti ilẹ̀ Asiria. 19 Gbogbo wọn yóò gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ òkè àti pàlàpálá òkúta, lára koríko ̀gún àti gbogbo ibi ihò omi. 20 ọjọ́ náà, Olúwa yóò lo abẹ fífẹ́lẹ́ a láti ìkọjá odò Eufurate, ọba Asiria, láti irun orí àti ti àwọn ẹsẹ̀ yín, àti láti irùngbọ̀n yín kúrò pẹ̀. 21 ọjọ́ náà, ọkùnrin kan yóò máa sin ̀dọ́ abo màlúù kan àti ewúrẹ́ méjì. 22 Àti nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà wọn yóò máa fún un, yóò wàràǹkàṣì láti jẹ. Gbogbo àwọn ó ilẹ̀ náà yóò jẹ wàràǹkàṣì àti oyin. 23 ọjọ́ náà, ni gbogbo ibi àjàrà ó ẹgbẹ̀rún (1,000) ṣékélì fàdákà, ̀gún àti ̀wọ̀n nìkan ni yóò níbẹ̀. 24 Àwọn ènìyàn yóò máa lọ síbẹ̀ pẹ̀ọrun àti ọfà nítorí ̀gún àti ̀wọ̀n ni yóò bo gbogbo ilẹ̀ náà. 25 Àti orí àwọn òkè kéékèèké a ti ń fi ọkọ́ ro nígbà kan , lọ síbẹ̀ mọ́ nítorí ìbẹ̀̀gún àti ̀wọ̀n, wọn yóò di ibi a ń da màlúù lọ, àti ibi ìtẹ̀mọ́lẹ̀ fún àwọn àgùntàn kéékèèké.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também