Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 12

Orin ìyìn

1 ọjọ́ náà ni ìwọ ó ,

"Èmi ó yìn ́, Olúwa.

ó tilẹ̀ jẹ́ ò ti bínú mi

ìbínú rẹ ti kúrò níbẹ̀

ìwọ ti nínú.

2 Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,

èmi yóò gbẹ́kẹ̀e èmi yóò bẹ̀.

Olúwa, Olúwa náà ni agbára à mi àti orin ìn mi,

òun ti di ìgbàlà mi."

3 Pẹ̀ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi

láti inú kànga ìgbàlà.

4 ọjọ́ náà, ìwọ yóò ,

"Fi ọpẹ́ fún Olúwa, pe orúkọ rẹ̀,

jẹ́ ó di mọ̀ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,

ohun ó ti ṣe

o kéde a ti gbé

orúkọ rẹ̀ ga.

5 Kọ orin Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun ó lógo,

jẹ́ èyí di mọ̀ fún gbogbo ayé.

6 Kígbe sókè o kọrin fún ayọ̀, ̀yin ènìyàn Sioni,

nítorí títóbi ni ẹni mímọ́ kan ṣoṣo

ti Israẹli láàrín yín."

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também