Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 24

Ìparun Olúwa lórí ilẹ̀ ayé

1 Kíyèsi i, Olúwa yóò sọ ohun

gbogbo dòfo ilẹ̀ ayé

yóò pa á run

òun yóò pa ojú u rẹ̀ rẹ́

yóò fọ́n àwọn olùgbé ibẹ̀ káàkiri

2 bákan náà ni yóò

fún àlùfáà àti àwọn ènìyàn,

fún ̀àti ọmọ ̀dọ̀,

fún ìyá-ilé àti ọmọbìnrin,

fún olùtà àti olùrà,

fún ayáni àti atọrọ

fún ayánilówó àti onígbèsè.

3 Ilé ayé ni a ó sọ di ahoro pátápátá

a ó jẹ gbogbo rẹ̀ run.

Olúwa ni ó ti sọ ̀rọ̀ yìí.

4 Ilẹ̀ ayé ti gbẹ ó ,

ayé ń ṣòjòjò, àárẹ̀ un,

àwọn ẹni gíga ilẹ̀ ayé nínú ìpọ́njú

5 àwọn ènìyàn ayé ti á jẹ́;

wọ́n ti pa àwọn òfin run

wọ́n ṣe lòdì àwọn ìlànà

wọ́n ti ba májẹ̀ayérayé jẹ́.

6 Nítorí náà, ègún kan ti jẹ ayé run;

àwọn ènìyàn rẹ̀ láti ru ̀bi wọn.

Nítorí náà, àwọn olùgbé ayé ti gbiná dànù,

àwọn ̀tàhóró .

7 Wáìnì tuntun ti gbẹ, àjàrà ti rọ,

gbogbo àwọn aláríyá kérora.

8 24.8: If 18.22. Àríyá ti ṣaworo ti dákẹ́

ariwo àwọn ń ṣàjọyọ̀ ti dáwọ́ dúró

ayọ̀ dùùrù ti dákẹ́ jẹ́́.

9 ṣe é ṣe fún wọn láti máa mu wáìnì pẹ̀orin kíkọ mọ́

ọtí líle ti di ìkorò fún àwọn ̀mu.

10 Ìlú a run ti dahoro,

ẹnu-ọ̀àbáwọlé kọ̀̀kan ni a pa.

11 òpópónà ni wọ́n ti ń kígbe fún wáìnì

gbogbo ayọ̀ wọn ti di ìbànújẹ́,

gbogbo àríyá ni a kúrò lórí ilẹ̀ ayé.

12 Ìlú ni a ti fi sílẹ̀ ahoro,

ìlẹ̀kùn rẹ̀ ni a pa bámú bámú.

13 Bẹ́̀ ni yóò orí ilẹ̀ ayé

àti láàrín àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀,

gẹ́gẹ́ ìgbà a lu igi olifi,

tàbí gẹ́gẹ́ i pàǹtí ó ṣẹ́lẹ́yìn

a kórè èso tán.

14 Wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n fún ayọ̀;

láti ìwọ̀-oòrùn ni wọn yóò ti polongo

ọláńlá Olúwa.

15 Nítorí náà ìlà-oòrùn fi ògo fún Olúwa;

gbé orúkọ Olúwa ga, àní

Ọlọ́run Israẹli,

àwọn erékùṣù ti inú Òkun.

16 Láti òpin ayé ni a ti gbọ́ orin;

"Ògo ni fún olódodo n ."

Ṣùgbọ́n mo , "Mo ṣègbé, mo ṣègbé!

"Ègbé ni fún mi!

Alárékérekè dalẹ̀!

Pẹ̀ìhàlẹ̀ ni àgàbàgebè fi dalẹ̀!"

17 Ìpayà, isà òkú, àti ìdẹ̀kùn ń dúró ́,

ìwọ ènìyàn ilẹ̀ ayé.

18 Ẹnikẹ́ni ó nítorí ariwo ìpayà

yóò ṣubú sínú ihò,

ẹnikẹ́ni ó yọ́ jáde nínú ihò

ni ìdẹ̀kùn yóò gbámú.

Ibodè ̀run ti ṣíṣí sílẹ̀,

ìpìlẹ̀ ayé tìtì.

19 Ilẹ̀ ayé ti fọ́

ilẹ̀ ayé ti fọ́ dànù,

a ti mi ilẹ̀ ayé rìrìrìrì.

20 Ilẹ̀ ayé gbiri ̀mùtí,

ó síwá sẹ́yìn ahéré nínú afẹ́fẹ́;

̀bi ìṣọ̀tẹ̀ rẹ̀ ń pa á lẹ́

bẹ́̀ ó fi ṣubú láìní dìde mọ́.

21 ọjọ́ náà ni Olúwa yóò jẹ ́

gbogbo agbára ó lókè lọ́run

àti àwọn ọba ó lórí ilẹ̀ ayé.

22 A ó wọn jọ pọ̀,

gẹ́gẹ́ ará túbú jọ sínú ihò,

a ó wọ́n mọ́ inú túbú,

a ó bẹ̀ wọ́n lẹ́yìn ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́.

23 A ó rẹ òṣùpá sílẹ̀, ojú yóò ti oòrùn;

nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò jẹ ọba

orí òkè Sioni àti Jerusalẹmu,

àti níwájú àwọn àgbàgbà rẹ ògo.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também