Pular para o conteúdo
Publicidade

Isaiah 47

Ìṣubú Babeli

1 47.1-15: Isa 13.1–14.23; Jr 50.1–51.64; Hk 1–2. "Sọ̀kalẹ̀, jókòó nínú eruku,

wúńdíá ọmọbìnrin Babeli;

jókòó ilẹ̀ láìsí ìtẹ́,

ọmọbìnrin àwọn ará Babeli.

A yóò ́ aláìlókun àti ẹlẹgẹ́ mọ́.

2 òkúta-ọlọ o lọ ìyẹ̀fun;

ìbòjú rẹ kúrò.

aṣọ ẹsẹ̀ rẹ sókè, aṣọ itan,

o la odò wọ̀n-ọn-nì kọjá.

3 Ìhòhò rẹ ni a ó síta

àti ìtìjú rẹ ni a ó ṣí sílẹ̀.

Èmi yóò gba ̀san,

Èmi yóò ẹnìkan ."

4 Olùràpadà wa Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀

òun ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.

5 "Jókòó ìdákẹ́ jẹ́́, lọ sínú òkùnkùn,

ọmọbìnrin àwọn ará Babeli;

a yóò ́ ọbabìnrin

àwọn ilẹ̀ ọba mọ́.

6 Inú mi àwọn ènìyàn mi

mo ba ogún mi jẹ́,

mo fi wọ́n lọ́wọ́,

Ìwọ síjú àánú wọ́n.

Lórí àwọn arúgbó pẹ̀

o gbé àjàgà ó wúwo .

7 Ìwọ , Èmi yóò tẹ̀síwájú títí láé

ọbabìnrin ayérayé!

Ṣùgbọ́n ìwọ kíyèsi nǹkan wọ̀nyí

tàbí o ronú nípa ohun ó ṣẹlẹ̀.

8 47.8: If 18.7. "Nísinsin yìí, tẹ́sílẹ̀, ìwọ oníwọ̀ra ̀

o kẹ̀tẹ̀ǹfẹ̀ nínú ààbò rẹ

o ń sọ fún ara rẹ ,

Èmi ni, ṣí ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.

Èmi yóò di opó

tàbí n pàdánù àwọn ọmọ.

9 47.9: If 18.8. Méjèèjì yìí ni yóò sórí rẹ

láìpẹ́ jọjọ, ọjọ́ kan náà:

pípàdánù ọmọ àti dídi opó.

Wọn yóò sórí rẹ ̀kúnrẹ́rẹ́,

pẹ̀lúpẹ̀àwọn ìṣe oṣó rẹ

àti àwọn èpè rẹ ko lágbára.

10 Ìwọ ti ìgbẹ́kẹ̀nínú ìwà ìkà rẹ

ó ti , ẹni ó mi?

Ọgbọ́n àti òye rẹ ti ṣì ́ lọ́

nígbà o fún ara rẹ ,

Èmi ni, ẹlòmíràn lẹ́yìn mi.

11 Ìparun yóò

bẹ́̀ ni ìwọ yóò mọ ̀láti e kúrò.

Àjálù kan yóò ṣubú ́

o yóò le è fi ètùtù kúrò;

òfò kan o le faradà ni

yóò lójijì oríì rẹ.

12 "Tẹ̀síwájú nígbà náà, pẹ̀àfọ̀ṣẹ rẹ

àti pẹ̀ìwà oṣó rẹ gbogbo,

o ti ń ṣiṣẹ́ fún láti ìgbà èwe rẹ .

Bóyá o le è ṣàṣeyọrí,

bóyá o le è rúgúdù sílẹ̀.

13 Gbogbo ìmọ̀ràn o ti gbà ni

ó ti sọ ́ di akúrẹtẹ̀!

Jẹ́ àwọn awòràwọ̀ rẹ bọ́ síwájú,

àwọn awòràwọ̀ wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀

láti oṣù oṣù,

jẹ́ wọ́n gbà ́ lọ́wọ́ ohun ó ń bọ̀ .

14 Lóòótọ́ wọ́n dàbí ìṣẹ́pẹ́ igi;

iná ni yóò wọn dànù.

Wọn kúkú gba ara wọn

lọ́wọ́ agbára iná náà.

èédú láti ara ẹnikẹ́ni gbóná

níhìn-ín iná ènìyàn le jókòó .

15 Gbogbo ohun wọ́n ṣe fún nìyìí

gbogbo èyí o ṣíṣẹ́ pẹ̀u rẹ̀

o ti ń kiri láti ìgbà èwe.

̀kọ̀̀kan wọn ń lọ nínú àṣìṣe rẹ̀;

ẹyọ ẹnìkan ó gbà ́.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também