Pular para o conteúdo
Publicidade

Esteri 8

Àṣẹ ọba nítorí àwọn Júù

1 ọjọ́ kan náà ni ọba Ahaswerusi fún Esteri ayaba ilé e Hamani, ̀àwọn Júù. Mordekai síwájú ọba, nítorí Esteri ti sọ ó ṣe jẹ́ ọba. 2 Ọba bọ́ òrùka dídán an rẹ̀, èyí ó ti gbà lọ́wọ́ Hamani ó fi fún Mordekai, Esteri yàn án gẹ́gẹ́ olórí ilé e Hamani.

3 Esteri tún bẹ ọba lórí ìkúnlẹ̀, pẹ̀omijé lójú. Ó bẹ̀ ́ ó fi òpin ètò búburú Hamani ará Agagi, èyí ó ti pète fún àwọn Júù. 4 Nígbà náà ni ọba na ̀aládé wúrà Esteri ó dìde, ó dúró níwájú rẹ̀.

5 Ó , "ó wu ọba, ó bọ̀wọ̀ fún mi pẹ̀ojúrere ó ohun ó dára ni láti ṣe, ó inú dídùn pẹ̀mi, jẹ́ a kọ ìwé àṣẹ láti ète Hamani ọmọ Hammedata, ará Agagi, ó kọ́ pàṣẹ a pa àwọn Júù wọ́n gbogbo àgbáyé ìjọba ọba run. 6 Nítorí báwo ni èmi yóò ṣe fi ara á èmi yóò ibi máa ṣubú lu àwọn ènìyàn mi? Báwo ni èmi yóò ṣe fi ara á, èmi yóò máa wo ìparun àwọn ìdílé mi?"

7 Ọba Ahaswerusi Esteri ayaba àti Mordekai ará a Júù náà lóhùn , "Nítorí Hamani kọlu àwọn ará a Júù, èmi ti fi ilé e rẹ̀ fún Esteri, wọ́n ti ṣo ó kọ́ sórí igi. 8 Nísinsin yìí, kọ ìwé àṣẹ mìíràn orúkọ ọba àwọn Júù ṣe jẹ́ pàtàkì , o fi òrùka ọba ṣe èdìdì í, nítorí àkọsílẹ̀ a ti kọ orúkọ ọba a fi òrùka ọba ṣe èdìdì a yìí padà."

9 Lẹ́sẹ̀kan náà àwọn akọ̀ọba péjọ ọjọ́ kẹtàlélógún oṣù kẹta, oṣù Sifani. Wọ́n kọ gbogbo àṣẹ Mordekai àwọn Júù, àti àwọn alákòóso baálẹ̀ àti àwọn ọlọ́ìgbèríko mẹ́tàdínláàádóje (127) ó lọ láti India títí ó fi Kuṣi. a kọ àṣẹ náà ìlànà ìgbèríko kọ̀̀kan ṣe ń kọ̀àti èdè olúkúlùkù àti pẹ̀àwọn Júù ìlànà wọ́n ṣe ń kọ̀àti èdè e wọn. 10 Mordekai fi àṣẹ ọba Ahaswerusi kọ̀, ó fi òrùka ọba ṣe èdìdì i rẹ̀, ó rán an lọ kíákíá, ó rán àwọn ìránṣẹ́ ayaba, tiwọn yára àṣà àwọn wọ́n ń gun ẹṣin ó yára, pàtàkì èyí a ń bọ́ fún ọba.

11 Àṣẹ ọba ̀dọ̀ àwọn Júù gbogbo ìlú láti ara wọn jọ wọn dáàbò bo ara wọn; láti pa, láti run àti láti kọlu ogunkógun orílẹ̀-èdè kórílẹ̀ èdè kankan tàbí ìgbèríko ó fẹ́ kọlù wọ́n, àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ wọn; gbogbo ohun ìní àwọn ̀wọn. 12 Ọjọ́ a yàn fún àwọn Júù gbogbo agbègbè ọba Ahaswerusi láti ṣe nǹkan yìí ni ọjọ́ kẹtàlá èyí í ṣe oṣù kejìlá, oṣù Addari. 13 Ọkàn ìwé àṣẹ náà ni a gbé jáde gẹ́gẹ́ òfin gbogbo ìgbèríko jẹ́ ó di mọ̀ fún gbogbo ènìyàn ìlú nítorí àwọn Júù yóò le è múra ọjọ́ náà láti gbẹ̀san fún ara wọn lára àwọn ̀wọn.

14 Bẹ́̀ ni àwọn ìránṣẹ́ ayaba tiwọn yára àṣà wọ́n ń gun ẹṣin ọba, sáré jáde, wọ́n sáré lọ nípa àṣẹ ọba. A tún gbé àṣẹ náà jáde ilé ìṣọ́ ti Susa.

15 Mordekai kúrò níwájú ọba, ó wọ aṣọ aláró àti funfun, ó adé e wúrà ńlá pẹ̀ìgbànú elése àlùkò dáradára, ìlú Susa ṣe àjọyọ̀ ńlá. 16 Àsìkò ìdùnnú àti ayọ̀, inú dídùn àti ọlá ni ó jẹ́ fún àwọn Júù. 17 gbogbo ìgbèríko àti gbogbo ìlú, gbogbo ibi àṣẹ ọba , ni ayọ̀ àti inú dídùn ti láàrín àwọn Júù, wọ́n ń ṣe àsè àti àjọyọ̀. ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ìlú tókù sọ ara wọn di Júù nítorí ̀àwọn Júù wọ́n.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também