Pular para o conteúdo
Publicidade

Esteri 9

Àwọn Júù yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun

1 ọjọ́ kẹtàlá oṣù kejìlá, oṣù Addari, ó yẹ a àṣẹ ọba pa ìmúṣẹ. ọjọ́ yìí ni ̀àwọn Júù àwọn yóò borí i wọn, ṣùgbọ́n nísinsin yìí a ti yìí padà, àwọn Júù na ọwọ́ agbára ga lórí àwọn ó kórìíra wọn. 2 Àwọn Júù péjọ àwọn ìlú u wọn gbogbo agbègbè ọba Ahaswerusi láti kọlu àwọn ń ìparun wọn. ẹnikẹ́ni ó dojúkọ wọ́n, nítorí gbogbo àwọn ènìyàn ìlú tókù ń bẹ̀u wọn. 3 Gbogbo àwọn ọlọ́ìgbèríko, àwọn alákòóso, àwọn baálẹ̀ àti àwọn onídàájọ́ ọba ran àwọn Júù lọ́wọ́, nítorí wọ́n bẹ̀u Mordekai. 4 Mordekai jẹ́ ẹni pàtàkì ààfin ọba, òkìkí rẹ̀ tàn jákèjádò àwọn ìgbèríko, ó agbára kún agbára.

5 Àwọn Júù gbogbo àwọn ̀a wọn lulẹ̀ pẹ̀idà, wọ́n pa wọ́n, wọ́n run wọ́n, wọ́n ṣe ohun ó wọ́n àwọn ó kórìíra wọn. 6 ilé ìṣọ́ ti Susa, àwọn Júù pa ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ọkùnrin run. 7 Wọ́n tún pa Parṣandata, Dalfoni, Aspata, 8 Porata, Adalia, Aridata, 9 Parmaṣta, Arisai, Aridai àti Faisata. 10 Àwọn ọmọkùnrin mẹ́wẹ̀̀wọ́n jẹ́ ọmọ Hamani, ọmọ Hammedata, ̀àwọn Júù. Ṣùgbọ́n wọn fi ọwọ́ wọn ìkógun un wọn.

11 ọjọ́ náà gan an ni a iye àwọn a pa ilé ìṣọ́ ti Susa fún ọba. 12 Ọba sọ fún Esteri ayaba , "Àwọn Júù ti pa ̀́dẹ́gbẹ̀ta (500) ọkùnrin àti àwọn ọmọkùnrin mẹ́wẹ̀̀i ṣe ọmọ Hamani ilé ìṣọ́ Susa run. ni wọ́n ṣe gbogbo ìgbèríko ọba tókù? Báyìí ni ̀bẹ̀ rẹ? A ó fi fún . ni ìbéèrè rẹ? A ó tún fi fún ."

13 Esteri dáhùn , "ó tẹ́ ọba lọ́rùn, fún àwọn Júù ó Susa àṣẹ láti ṣe gẹ́gẹ́ wọ́n ti ṣe òní wọn ṣe bákan náà ̀la, a so àwọn ọmọkùnrin Hamani mẹ́wẹ̀̀náà rọ̀ sórí igi."

14 Nítorí náà ọba pàṣẹ a ṣe bẹ́̀. A gbé àṣẹ kan jáde Susa, wọ́n so àwọn ọmọkùnrin mẹ́wẹ̀̀Hamani kọ́. 15 Àwọn Júù ó Susa péjọ ọjọ́ kẹrìnlá oṣù Addari, wọ́n pa ̀́dúnrún (300) ọkùnrin Susa, ṣùgbọ́n wọn fi ọwọ́ wọn ìkógun un wọn.

16 Lákokò yìí, àwọn tókù nínú àwọn Júù wọ́n agbègbè ọba náà tún ara wọn jọ láti dáàbò bo ara wọn wọn sinmi lọ́wọ́ àwọn ̀a wọn. Wọ́n pa ẹgbàá mẹ́tàdínlógójì ó ẹgbẹ̀rin (75,000) àwọn ó kórìíra wọn ṣùgbọ́n wọn fi ọwọ́ wọn ìkógun un wọn. 17 Èyí ṣẹlẹ̀ ọjọ́ kẹtàlá oṣù Addari, wọ́n sinmi ọjọ́ kẹrìnlá, wọ́n ṣe ọjọ́ náà ọjọ́ àsè àti ayọ̀.

Àjọyọ̀ Purimu

18 Àwọn Júù ó Susa, ara wọn jọ ọjọ́ kẹtàlá àti ọjọ́ kẹrìnlá, nígbà ó di ọjọ́ kẹ́̀dógún wọ́n sinmi wọ́n ṣe ọjọ́ náà ọjọ́ àsè àti ayọ̀.

19 Nítorí náà ni àwọn Júù wọ́n ń gbé ìletò ṣe pa ọjọ́ kẹrìnlá oṣù Addari mọ́ gẹ́gẹ́ ọjọ́ ayọ̀ àti ọjọ́ àsè, ọjọ́ wọ́n ń fún ara wọn ̀bùn.

20 Mordekai ṣe àkọsílẹ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí, ó kọ ìwé ránṣẹ́ gbogbo àwọn Júù jákèjádò àgbáyé ọba Ahaswerusi, ó tòsí àti àwọn ó jìnnà réré, 21 láti máa ṣe àjọyọ̀ ọjọ́ kẹrìnlá àti ọjọ́ kẹ́̀dógún oṣù Addari ọdọọdún. 22 gẹ́gẹ́ àkókò àwọn Júù gba ìsinmi kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀a wọn, àti oṣù ìbànújẹ́ wọn padà di ayọ̀ àti ọjọ́ ̀fọ̀ wọn di ọjọ́ àjọyọ̀. Ó kọ ́ wọn láti máa pa ọjọ́ náà mọ́ gẹ́gẹ́ ọjọ́ àsè àti ọjọ́ ayọ̀ wọn máa fi oúnjẹ fún ara wọn, wọn máa fi ̀bùn fún àwọn aláìní.

23 Bẹ́̀ ni àwọn Júù gbà láti máa ṣe àjọyọ̀ wọ́n ti bẹ̀rẹ̀, wọ́n ń ṣe Mordekai ti kọ̀wọn. 24 Nítorí Hamani ọmọ Hammedata, ará Agagi, ̀gbogbo àwọn Júù, ti gbèrò àwọn Júù láti pa wọ́n run, ó ti di puri (èyí í ṣe ìbò) fún ìsọdahoro àti ìparun wọn. 25 Ṣùgbọ́n nígbà Esteri sọ nípa ìṣọ̀tẹ̀ náà fún ọba, ó kọ̀àṣẹ kan jáde ète búburú Hamani ti pa àwọn Júù ó padà orí òun fúnra rẹ̀, àti a gbé òun àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ kọ́ sórí igi. 26 (Nítorí náà a pe àwọn ọjọ́ wọ̀nyí Purimu, láti ara ̀rọ̀ puri). Nítorí ohun gbogbo a kọ sínú ìwé yìí àti nítorí ohun wọ́n ti àti ohun ó ti ṣẹlẹ̀ wọn, 27 àwọn Júù fi lélẹ̀, wọ́n gbà á gẹ́gẹ́ ìlànà fún ara wọn àti fún irú àwọn ọmọ wọn àti gbogbo àwọn ó darapọ̀ mọ́ wọn, kúrò, wọn yóò máa pa àwọn ọjọ́ méjèèjì yìí mọ́ gbogbo ọdún, gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ àti àkókò a yàn. 28 A gbọdọ̀ máa ṣe ìrántí àwọn ọjọ́ wọ̀nyí a máa pa wọ́n mọ́ ìrandíran gbogbo ìdílé, àti gbogbo ìgbèríko àti gbogbo ìlú. A gbọdọ̀ máa ṣe àwọn ọjọ́ Purimu wọ̀nyí àárín àwọn Júù, bẹ́̀ ni gbọdọ̀ di ohun ìgbàgbé láàrín irú àwọn ọmọ wọn.

29 Bẹ́̀ ni Esteri ayaba, ọmọbìnrin Abihaili, pẹ̀Mordekai ará a Júù, kọ̀pẹ̀àṣẹ láti fi ìdí ìwé kejì nípa Purimu yìí múlẹ̀. 30 Mordekai kọ ìwé ránṣẹ́ gbogbo àwọn Júù, ìgbèríko mẹ́tàdínláàádóje (127) ilẹ̀ ọba Ahaswerusi ̀rọ̀ àlàáfíà àti òtítọ́. 31 Láti fi ìdí àwọn ọjọ́ Purimu yìí múlẹ̀ àkókò wọ́n yàn, gẹ́gẹ́ Mordekai ará Juda, àti Esteri ayaba ti pa á láṣẹ fún wọn, àti wọ́n ṣe fi lélẹ̀ fún ara wọn àti irú àwọn ọmọ wọn ìbámu pẹ̀àkókò àwẹ̀ àti ẹkún wọn. 32 Àṣẹ Esteri fi ìdí ìlànà Purimu wọ̀nyí múlẹ̀, a kọ ́ sínú ìwé àkọsílẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também