Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 4

Ẹbọ ̀ṣẹ̀

1 Olúwa sọ fún Mose , 2 4.2-12: Nu 15.27-29."Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli , ẹnìkan ṣẹ̀ láìmọ̀, ó ṣe ohun yẹ ṣe ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa.

3 " àlùfáà a fi òróró yàn ṣẹ̀, ó ̀bi sórí àwọn ènìyàn, ó gbọdọ̀ ọmọ akọ màlúù lábùkù fún Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ fún ̀ṣẹ̀ ó ṣẹ̀. 4 ó ̀dọ́ màlúù síwájú Olúwa ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. ó gbé ọwọ́ rẹ̀ e lórí, ó pa á níwájú Olúwa. 5 àlùfáà a fi òróró yàn díẹ̀ nínú ̀jẹ̀ akọ màlúù, ó gbé e lọ sínú àgọ́ ìpàdé. 6 ó ti ìka bọ inú ̀jẹ̀ náà ó wọ́n díẹ̀ nínú rẹ̀ ̀̀méje níwájú Olúwa, níwájú aṣọ títa ibi mímọ́. 7 Àlùfáà yóò tún díẹ̀ nínú ̀jẹ̀ náà sórí ìwo pẹpẹ tùràrí níwájú Olúwa nínú àgọ́ ìpàdé. ó da gbogbo ̀jẹ̀ akọ màlúù tókù ìsàlẹ̀ pẹpẹ ẹbọ sísun ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 8 ó yọ gbogbo ̀ń bẹ nínú akọ màlúù ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà ̀ó bo nǹkan inú àti gbogbo ohun so mọ́ wọn. 9 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀̀wọn ń bẹ lẹ́bàá ìhà àti ̀ó bo ̀dọ̀, ó yọ ́ pẹ̀kíndìnrín. 10 Gẹ́gẹ́ a ṣe ń yọ ̀kúrò lára màlúù a fi ẹbọ àlàáfíà; àlùfáà yóò sun wọ́n lórí pẹpẹ ẹbọ sísun. 11 Ṣùgbọ́n awọ màlúù àti gbogbo ara rẹ̀, àti ẹsẹ̀, gbogbo nǹkan inú àti ìgbẹ́ rẹ̀. 12 Èyí túmọ̀ gbogbo ìyókù akọ màlúù náà ni gbé jáde síta lẹ́yìn ibùdó ibi a sọ di mímọ́ níbi à ń da eérú , sun wọ́n lórí iná igi, níbi eérú a kójọ.

13 4.13-21: Nu 15.22-26. " gbogbo àpapọ̀ ènìyàn Israẹli ṣèèṣì ṣẹ̀, wọ́n ṣe ohun yẹ wọ́n ṣe ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa, ó tilẹ̀ jẹ́ àpapọ̀ ènìyàn náà mọ̀ ̀rọ̀ náà, wọ́n jẹ̀bi. 14 Nígbà wọ́n mọ̀, gbogbo ìjọ ènìyàn yóò akọ màlúù àgọ́ ìpàdé gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀. 15 àwọn àgbàgbà ìjọ Israẹli gbé ọwọ́ lórí akọ ọmọ màlúù náà níwájú Olúwa. 16 àlùfáà a fi òróró yàn díẹ̀ lára ̀jẹ̀ akọ ọmọ màlúù náà sínú àgọ́ ìpàdé. 17 ó ti ìka rẹ̀ bọ inú ̀jẹ̀ náà ó wọn ̀̀méje níwájú Olúwa níbi aṣọ títa ẹnu-ọ̀. 18 ó díẹ̀ nínú ̀jẹ̀ náà sórí ìwo pẹpẹ níwájú Olúwa nínú àgọ́ ìpàdé. Ìyókù ̀jẹ̀ náà ni ó ìsàlẹ̀ pẹpẹ ẹbọ sísun ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé. 19 ó yọ gbogbo ̀kúrò lára rẹ̀, ó sun ún lórí pẹpẹ. 20 ó ṣe akọ ọmọ màlúù yìí gẹ́gẹ́ ó ṣe ṣe akọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ṣe ètùtù fún wọn, á ó dáríjì wọ́n. 21 Lẹ́yìn náà ni yóò sun màlúù yìí lẹ́yìn ibùdó, yóò sun ún gẹ́gẹ́ ṣe sun màlúù àkọ́kọ́. Èyí ni ẹbọ ̀ṣẹ̀ fún gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli.

22 " olórí kan ṣèèṣì ṣẹ̀ láìmọ̀ ó ṣe ohun yẹ ó ṣe ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ó jẹ̀bi. 23 Nígbà a sọ ̀ṣẹ̀ rẹ̀ fún un, ó gbọdọ̀ akọ ewúrẹ́ àbùkù gẹ́gẹ́ ẹbọ rẹ̀. 24 ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lórí ewúrẹ́ náà, ó pa á níbi wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ sísun níwájú Olúwa. Ẹbọ ̀ṣẹ̀ ni. 25 Lẹ́yìn èyí, àlùfáà ti ìka rẹ̀ bọ inú ̀jẹ̀ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà, ó fi orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, ó da ̀jẹ̀ yòókù ìsàlẹ̀ pẹpẹ. 26 ó sun gbogbo ̀rẹ̀ lórí pẹpẹ ó ṣe sun ̀ọrẹ àlàáfíà. Báyìí àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ̀ṣẹ̀ ọkùnrin náà, a ó dáríjì í.

27 4.27-31: Nu 15.27,28. " ènìyàn nínú àwọn ará ìlú ṣèèṣì ṣẹ̀ láìmọ̀ ó ṣe ohun yẹ ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa, ó jẹ̀bi. 28 Nígbà a sọ ̀ṣẹ̀ rẹ̀ fún un, ó gbọdọ̀ abo ewúrẹ́ àbùkù gẹ́gẹ́ ẹbọ fún ̀ṣẹ̀ rẹ̀. 29 ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lórí ewúrẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà, ó pa á níbi ẹbọ sísun. 30 Àlùfáà yóò ti ìka rẹ̀ bọ́ ̀jẹ̀ náà, yóò fi orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, ó da ìyókù ̀jẹ̀ náà ìsàlẹ̀ pẹpẹ. 31 ó yọ gbogbo ̀ẹran náà gẹ́gẹ́ ṣe yọ ̀ẹran fún ọrẹ àlàáfíà. àlùfáà sun ̀yìí lórí pẹpẹ òórùn dídùn Olúwa. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, a ó dáríjì í.

32 " ó ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀, ó abo lábùkù. 33 ó gbé ọwọ́ rẹ̀ e lórí, ó pa á fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ níbi wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ sísun. 34 Àlùfáà yóò ti ìka rẹ̀ bọ inú ̀jẹ̀ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà, yóò fi orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, yóò da ìyókù ̀jẹ̀ náà ìsàlẹ̀ pẹpẹ. 35 ó yọ gbogbo ̀rẹ̀ ti yọ ̀lára ̀dọ́-àgùntàn ọrẹ àlàáfíà, àlùfáà yóò sun ún orí pẹpẹ, lórí ọrẹ a fi iná sun Olúwa. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, nítorí ̀ṣẹ̀ ó sẹ̀, a ó dáríjì í.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também