Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 8

Ìfinijoyè àlùfáà Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀

1 8.1-36: Ek 29.1-37. Olúwa sọ fún Mose , 2 "Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, aṣọ wọn, òróró ìtasórí, akọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, àgbò méjì àti apẹ̀rẹ̀ a àkàrà aláìwú sínú rẹ̀. 3 o gbogbo ìjọ ènìyàn jọ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé." 4 Mose ṣe Olúwa ti pa á láṣẹ fún un, gbogbo ènìyàn péjọ ẹnu-ọ̀àgọ́ àjọ.

5 Mose sọ fún ìjọ ènìyàn , "Èyí ni ohun Olúwa ti pàṣẹ á ṣe." 6 Nígbà náà ni Mose Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ síwájú, ó fi omi wẹ̀ wọ́n. 7 Ó fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ Aaroni, ó fi àmùrè í, ó wọ̀ ́ efodu; aṣọ ìgúnwà, ó tún wọ̀ ́ ni aṣọ ìlekè oyè àlùfáà ó ìgbànú a ṣe ọnà dáradára . 8 Ó fi ìgbàyà àyà rẹ̀, ó fi Urimu àti Tumimu ibi ìgbàyà náà. 9 Ó e fìlà, ó fi àwo wúrà í ṣe adé mímọ́ síwájú rẹ̀ gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

10 Mose fi òróró ìtasórí ya àgọ́ àti ohun gbogbo nínú rẹ̀ mímọ́. 11 Ó wọ́n díẹ̀ nínú òróró yìí sórí pẹpẹ lẹ́̀méje, ó ta òróró sórí pẹpẹ àti gbogbo ohun èlò àti agbada pẹ̀ohun gbé agbada yìí dúró láti á mímọ́, 12 ó da díẹ̀ lára òróró ìtasórí yìí sórí Aaroni, ó á mímọ́. 13 Lẹ́yìn èyí àwọn ọmọ Aaroni síwájú, ó fi ̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n, ó fi àmùrè dìwọ́n lára, ó fi fìlà wọn lórí gẹ́gẹ́ Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

14 Ó akọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ gbọ́wọ́ orí ẹran náà. 15 Mose pa akọ màlúù náà, ó ti ìka bọ inú ̀jẹ̀ náà, ó fi orí gbogbo ìwo pẹpẹ láti wẹ pẹpẹ náà mọ́. Ó da ìyókù ̀jẹ̀ náà ìsàlẹ̀ pẹpẹ. Bẹ́̀ ó ṣe á mímọ́ láti ṣe ètùtù fún un. 16 Mose tún gbogbo ̀ó bo nǹkan inú, èyí ó bo ̀dọ̀, kíndìnrín méjèèjì àti ̀wọn, ó sun gbogbo rẹ̀ lórí pẹpẹ. 17 Ṣùgbọ́n akọ màlúù yìí pẹ̀awọ àti ara ẹran àti ìgbẹ́ rẹ̀ ó sun lẹ́yìn ibùdó gẹ́gẹ́ Olúwa ti paláṣẹ fún Mose.

18 Lẹ́yìn náà àgbò fún ẹbọ sísun Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ gbọ́wọ́ orí àgbò náà. 19 Mose pa àgbò náà, ó wọ́n ̀jẹ̀ rẹ̀ pẹpẹ náà . 20 Ó àgbò náà wẹ́wẹ́, Mose sun orí àti àwọn ègé àti ̀rẹ̀. 21 Ó fi omi fọ gbogbo nǹkan inú àti ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sun odidi àgbò náà lórí pẹpẹ ẹbọ sísun òórùn dídùn, ẹbọ a fi iná ṣe Olúwa gẹ́gẹ́ Olúwa pàṣẹ fún Mose.

22 Ó àgbò kejì wa, èyí ni àgbò ìfinijoyè àlùfáà, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ gbọ́wọ́ e lórí. 23 Mose pa àgbò náà, ó díẹ̀ nínú ̀jẹ̀, ó tọ́ etí ̀tún Aaroni, sórí àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún àti ti ẹsẹ̀ ̀tún rẹ̀. 24 Mose tún àwọn ọmọ Aaroni síwájú, ó ̀jẹ̀ díẹ̀ ó fi etí ̀tún wọn, àtàǹpàkò ọwọ́ ̀tún wọn, ó wọ́n ̀jẹ̀ pẹpẹ náà . 25 Ó ̀ẹran náà, ìrù rẹ̀ ó lọ́ràá, gbogbo ̀lára nǹkan inú àti èyí ó bo ̀dọ̀, kíndìnrín méjèèjì àti ̀wọn pẹ̀itan ̀tún. 26 Lẹ́yìn náà àkàrà aláìwú , èyí níwájú Olúwa àti àkàrà a fi òróró ṣe, àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́, ó gbogbo rẹ̀ sórí ̀àti itan ̀tún ẹran náà. 27 Ó gbogbo àwọn nǹkan wọ̀nyí Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, wọ́n wọ́n gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì níwájú Olúwa. 28 Lẹ́yìn náà, Mose gba gbogbo rẹ̀ lọ́wọ́ wọn, ó sun wọn lórí ẹbọ sísun lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ ẹbọ ìfinijoyè àlùfáà òórùn dídùn, ẹbọ a fi iná sun Olúwa. 29 Mose igẹ̀ ẹran náà, èyí jẹ́ ìpín rẹ̀ nínú àgbò fún ìfinijoyè, ó í níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì, bi Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.

30 Mose díẹ̀ lára òróró ìtasórí àti díẹ̀ nínú ̀jẹ̀ láti orí pẹpẹ, ó wọ́n sára àwọn ọmọ Aaroni àti aṣọ rẹ̀, ó tún wọ́n sára àwọn ọmọ Aaroni àti aṣọ wọn. Bẹ́̀ Mose ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀aṣọ wọn mímọ́.

31 Mose sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ , "se ẹran náà ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé jẹ ́ níbẹ̀ pẹ̀àkàrà a láti inú apẹ̀rẹ̀ ọrẹ ìfinijoyè àlùfáà gẹ́gẹ́ mo ti pa á láṣẹ , Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni ó jẹ ́.’ 32 fi iná sun ìyókù àkàrà àti ẹran náà. 33 ṣe kúrò ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé fún ọjọ́ méje, títí ọjọ́ ìfinijoyè àlùfáà yín yóò fi , nítorí ìfinijoyè àlùfáà yín yóò gba ọjọ́ méje gbáko. 34 Ohun a ṣe lónìí jẹ́ ohun Olúwa ti pàṣẹ láti ṣe ètùtù fún yín. 35 gbọdọ̀ ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé lọ́sàn án àti lóru fún ọjọ́ méje ṣe ohun Olúwa fẹ́, ba à , nítorí ohun Olúwa pàṣẹ fún mi ni èyí."

36 Báyìí ni Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe ohun gbogbo Olúwa pàṣẹ láti ẹnu Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também