Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 24

Òróró òun àkàrà a tẹ́ síwájú Olúwa

1 24.1-4: El 27.20,21. Olúwa sọ fún Mose , 2 "Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli láti òróró ó mọ́ a fún láti ara olifi láti fi tan iná, fìtílà máa láì . 3 Lẹ́yìn aṣọ ìkélé ti ibi àpótí ̀ó inú àgọ́ ìpàdé, ni Aaroni ti tan iná náà níwájú Olúwa, láti ìrọ̀lẹ́ di àárọ̀ lójoojúmọ́. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran ń bọ̀. 4 Àwọn Àtùpà wọ́n lórí ojúlówó ̀fìtílà a fi wúrà ṣe níwájú Olúwa ni ó máa lójoojúmọ́.

5 24.5-9: Ek 25.30; 39.36; 40.23; Mt 12.4; Mk 2.26; Lk 6.4. "ìyẹ̀fun dáradára, o ṣe ìṣù àkàrà méjìlá, o lo ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n efa (èyí jẹ́ lita mẹ́rin ààbọ̀) fún ìṣù kọ̀̀kan. 6 wọ́n ̀ìlà méjì, mẹ́mẹ́ìlà kọ̀̀kan lórí tábìlì a fi ojúlówó wúrà bọ̀. Èyí ó níwájú Olúwa. 7 fi ojúlówó tùràrí ọnà kọ̀̀kan, gẹ́gẹ́ ìpín ìrántí láti dípò àkàrà, àti láti jẹ ẹbọ sísun Olúwa. 8 Àkàrà yìí ni gbé síwájú Olúwa nígbàkígbà, lọ́ṣọ̀̀ṣẹ̀, nítorí àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ májẹ̀ayérayé. 9 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni í. Wọ́n gbọdọ̀ jẹ ́ ibi mímọ́ torí ó jẹ́ ipa ó mọ́ jùlọ ti ìpín wọn ojoojúmọ́ nínú ọrẹ a fi iná ṣe Olúwa."

Ìsọ̀rọ̀-òdì àti ìjìyà rẹ̀

10 Ọmọkùnrin kan ìyá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Israẹli baba rẹ̀ jẹ́ ará Ejibiti. Ó jáde lọ láàrín àwọn ọmọ Israẹli, ìjà ṣẹlẹ̀ nínú àgọ́ láàrín òun àti ọmọ Israẹli kan. 11 Ọmọkùnrin arábìnrin Israẹli náà sọ̀rọ̀-òdì orúkọ Olúwa pẹ̀èpè, wọ́n un tọ Mose . (Orúkọ ìyá rẹ̀ Ṣelomiti, ọmọbìnrin Debiri, ti ̀Dani.) 12 Wọ́n fi í sínú túbú Olúwa to sọ ohun wọn yóò ṣe fún wọn.

13 Olúwa sọ fún Mose , 14 "asọ̀rọ̀-òdì náà jáde sẹ́yìn àgọ́, gbogbo àwọn ó gbọ́ ó ṣépè gbé ọwọ́ wọn lórí ọkùnrin náà láti fihàn ó jẹ̀bi. Lẹ́yìn náà ni gbogbo àpéjọpọ̀, sọ ́ òkúta pa. 15 Sọ fún àwọn ará Israẹli , ẹnikẹ́ni ṣépè Ọlọ́run rẹ̀, yóò jìyà ̀ṣẹ̀ rẹ̀. 16 Ẹnikẹ́ni ó sọ̀rọ̀-òdì orúkọ Olúwa ni pa, gbogbo àpéjọpọ̀ sọ ́ òkúta pa, yálà àlejò ni tàbí ọmọ bíbí Israẹli, ó ti sọ̀rọ̀-òdì orúkọ Olúwa, pípa ni pa á.

17 " Ẹni ó gba ̀ènìyàn pípa ni pa á. 18 Ẹni ó gba ̀ẹran ̀sìn ẹlòmíràn, ó a padà̀dípò ̀. 19 24.19,20: El 21.23-25; De 19.21; Mt 5.38.ẹnìkan pa ẹnìkejì rẹ̀ lára, ohunkóhun ó ṣe ni ṣe i. 20 ̀fún ̀, ojú fún ojú, eyín fún eyín; òun ti ṣe àbùkù ara ènìyàn, bẹ́̀ ni a ṣe i. 21 Ẹni ó lu ẹran pa, ó sán an padà; ẹni ó lu ènìyàn pa, a ó pa á. 22 24.22: El 12.19; Nu 9.14; 15.15,16,29.Òfin kan náà fún àlejò àti fún ọmọ Israẹli. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ "

23 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n asọ̀rọ̀-òdì náà lọ ̀yìn àgọ́, wọ́n sọ ́ òkúta pa. Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun Olúwa pàṣẹ fún Mose.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também