Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 9

Àwọn àlùfáà bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìránṣẹ́

1 ọjọ́ kẹjọ, Mose pe Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀àwọn àgbàgbà Israẹli. 2 Ó sọ fún Aaroni , "akọ ọmọ màlúù kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti àgbò kan fún ẹbọ sísun, méjèèjì jẹ́ aláìlábùkù, o wọn iwájú Olúwa. 3 o sọ fún àwọn ará Israẹli , òbúkọ kan fún ẹbọ ̀ṣẹ̀, ọmọ màlúù àti ̀dọ́-àgùntàn kan, méjèèjì jẹ́ ọlọ́dún kọ̀̀kan àbùkù fún ẹbọ sísun, 4 àti akọ màlúù kan àti àgbò kan fún ẹbọ àlàáfíà àti ẹbọ ohun jíjẹ a fi òróró láti fi ẹbọ iwájú Olúwa. Nítorí Olúwa yóò farahàn yín òní.’ "

5 Wọ́n gbogbo àwọn nǹkan Mose pàṣẹ iwájú àgọ́ ìpàdé, gbogbo ìjọ ènìyàn súnmọ́ tòsí, wọ́n dúró níwájú Olúwa. 6 Nígbà náà ni Mose , "Ohun Olúwa pàṣẹ fún yín láti ṣe nìyìí, ògo Olúwa à farahàn yín."

7 Mose sọ fún Aaroni , "ibi pẹpẹ o ẹbọ ̀ṣẹ̀ rẹ àti ẹbọ sísun rẹ, o ṣe ètùtù fún ara rẹ àti fún àwọn ènìyàn; ẹbọ ti àwọn ènìyàn náà, o ṣe ètùtù fún wọn gẹ́gẹ́ Olúwa ti pa á láṣẹ."

8 Aaroni ibi pẹpẹ, ó pa akọ ọmọ màlúù fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ ara rẹ̀. 9 Àwọn ọmọ Aaroni ̀jẹ̀ náà tọ̀ ́ , ó ti ìka ọwọ́ rẹ̀ bọ inú ̀jẹ̀ náà, ó fi orí ìwo pẹpẹ, ó da ìyókù ̀jẹ̀ náà ìsàlẹ̀ pẹpẹ. 10 Ó sun ̀, kíndìnrín àti ̀ó bo ̀dọ̀, èyí láti inú ẹbọ ̀ṣẹ̀, lórí pẹpẹ Olúwa ti pa á láṣẹ fún Mose. 11 Ó sun ara ẹran àti awọ rẹ̀ ̀yìn ibùdó.

12 Lẹ́yìn èyí ó pa ẹran fún ẹbọ sísun. Àwọn ọmọ Aaroni ̀jẹ̀ rẹ̀ tọ̀ ́ , ó wọn pẹpẹ náà . 13 Wọ́n ń ẹbọ sísun náà fún un ègé kọ̀̀kan, pẹ̀orí rẹ̀, ó sun gbogbo rẹ̀ lórí pẹpẹ. 14 Ó fọ nǹkan inú rẹ̀ àti ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sun wọ́n lórí ẹbọ sísun lórí pẹpẹ.

15 Aaroni ẹbọ jẹ́ ti àwọn ènìyàn . Ó òbúkọ èyí dúró fún ẹbọ ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn ó pa á, ó fi ẹbọ ̀ṣẹ̀ gẹ́gẹ́ ó ti ṣe ti àkọ́kọ́.

16 Ó ẹbọ sísun , ó u gẹ́gẹ́ ìlànà a fi lélẹ̀. 17 Ó tún mu ẹbọ ohun jíjẹ , ó bu ̀kúnwọ́ kan nínú rẹ̀, ó sun ún lórí pẹpẹ àfikún ẹbọ sísun àárọ̀.

18 9.18-21: Le 3.1-11. Ó pa akọ màlúù àti àgbò ẹbọ àlàáfíà fún àwọn ènìyàn. Àwọn ọmọ Aaroni ̀jẹ̀ ẹran náà tọ̀ ́ , ó wọn pẹpẹ náà . 19 Ṣùgbọ́n ̀akọ màlúù àti àgbò náà: ìrù rẹ̀ ó lọ́ràá, básí ̀, ̀kíndìnrín, àti ̀ó bo ̀dọ̀: 20 gbogbo rẹ̀ ni wọ́n lórí igẹ̀ ẹran náà. Aaroni sun ̀náà lórí pẹpẹ. 21 Aaroni fi igẹ̀ àti itan ̀tún ẹran náà níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ ẹbọ fífì Mose ṣe pa á láṣẹ.

22 9.22: Nu 6.22-26. Aaroni gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè àwọn ènìyàn, ó súre fún wọn. Lẹ́yìn ti ẹbọ ̀ṣẹ̀, ẹbọ sísun àti ẹbọ àlàáfíà, ó sọ̀kalẹ̀.

23 Mose àti Aaroni wọ inú àgọ́ ìpàdé. Nígbà wọ́n jáde, wọ́n súre fún àwọn ènìyàn, ògo Olúwa farahàn gbogbo ènìyàn. 24 Iná jáde láti ̀dọ̀ Olúwa, ó ẹbọ sísun àti ̀orí pẹpẹ. Nígbà gbogbo ènìyàn èyí wọ́n ìhó ayọ̀, wọ́n dojúbolẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também