Pular para o conteúdo
Publicidade

Lefitiku 10

Ikú Nadabu àti Abihu

1 Nadabu àti Abihu í ṣe ọmọ Aaroni àwo tùràrí kọ̀̀kan, wọ́n fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀, wọ́n iná àjèjì níwájú Olúwa, èyí lòdì àṣẹ Olúwa. 2 Torí èyí, iná jáde láti ̀dọ̀ Olúwa, ó wọn pa, wọ́n níwájú Olúwa. 3 Mose sọ fún Aaroni , "Ohun Olúwa ń sọ nípa rẹ̀ nìyìí nígbà ,

" àárín àwọn súnmọ́ mi,

Èmi yóò fi ara mi hàn mímọ́

ojú gbogbo ènìyàn

a ó ti bu ọlá fún mi.’ "

Aaroni dákẹ́.

4 Mose pe Miṣaeli àti Elsafani ọmọ Usieli í ṣe arákùnrin Aaroni, ó sọ fún wọn , ", gbé àwọn arákùnrin yín jáde kúrò níwájú ibi mímọ́ lọ ̀yìn ibùdó." 5 Wọ́n gbé wọn, pẹ̀̀àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọn ọrùn wọn lọ ̀yìn ibùdó Mose ti sọ.

6 Mose sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù, Eleasari àti Itamari , "ṣe ṣọ̀fọ̀ nípa ṣíṣe aláìtọ́irun yín tàbí ṣí orí yín sílẹ̀, gbọdọ̀ ya aṣọ, ṣe bẹ́̀, ó kùú, Olúwa yóò bínú gbogbo ìjọ ènìyàn. Ṣùgbọ́n àwọn ẹbí yín, àti gbogbo ilé Israẹli le è ṣọ̀fọ̀ lórí àwọn Olúwa fi iná parun. 7 ṣe kúrò ẹnu-ọ̀àgọ́ ìpàdé, kúrò níbẹ̀, ó ú, nítorí òróró ìtasórí Olúwa lórí yín." Wọ́n ṣe Mose ti .

8 10.8: El 44.21. Olúwa sọ fún Aaroni . 9 "Ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle mìíràn nígbàkígbà n lọ inú àgọ́ ìpàdé, ṣe bẹ́̀, ó ú, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún un yín láti ìrandíran. 10 gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀ láàrín mímọ́ àti àìmọ́, láàrín èérí àti àìléèérí. 11 gbọdọ̀ kọ́ àwọn ara Israẹli gbogbo àṣẹ Olúwa fún wọn láti ẹnu Mose."

12 10.12,13: Le 6.14-18. Mose sọ fún Aaroni, Eleasari àti Itamari àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù , "ẹbọ ohun jíjẹ ṣẹ́láti inú ẹbọ àfinásun Olúwa, jẹ ́ láìní ìwúkàrà nínú, lẹ́gbẹ̀́ pẹpẹ nítorí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ. 13 jẹ́ ibi mímọ́, nítorí òun ni ìpín rẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nínú ẹbọ a finá sun Olúwa nítorí bẹ́̀ ni mo ṣe pa á láṣẹ. 14 10.14,15: Le 7.30-34.Ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin rẹ le jẹ igẹ̀ ẹran a níwájú Olúwa àti itan wọ́n gbé síwájú Olúwa, jẹ wọ́n ibi a mímọ́, èyí ni a ti fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ gẹ́gẹ́ ìpín yín nínú ẹbọ àlàáfíà àwọn ara Israẹli. 15 Itan wọ́n àti igẹ̀ ẹran ni gbọdọ̀ pẹ̀̀ẹbọ a finá sun láti le è wọ́n níwájú Olúwa ẹbọ fífì. Èyí yóò jẹ́ ìpín tìrẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nígbà gbogbo Olúwa ṣe pàṣẹ."

16 Nígbà Mose wádìí nípa ewúrẹ́ ẹbọ ̀ṣẹ̀ i wọ́n ti sun ún, ó bínú Eleasari àti Itamari, àwọn ọmọ Aaroni yòókù, ó béèrè , 17 10.17: Le 6.24-26."Èéṣe jẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀ náà agbègbè ibi mímọ́? Ó jẹ́ mímọ́ jùlọ, a fi fún yín láti ̀ṣẹ̀ ìjọ ènìyàn kúrò nípa fífi ṣe ètùtù fún wọn níwájú Olúwa. 18 Níwọ́n ìgbà ̀jẹ̀ rẹ̀ Ibi Mímọ́, ̀ ti jẹ ewúrẹ́ náà agbègbè Ibi Mímọ́ mo ṣe pa á láṣẹ."

19 Aaroni Mose lóhùn , "Lónìí wọ́n ẹbọ ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun wọn níwájú Olúwa ni irú èyí tún ṣẹlẹ̀ mi. Ǹjẹ́ inú Olúwa yóò dùn mo jẹ ẹbọ ̀ṣẹ̀ lónìí?" 20 Nígbà Mose gbọ́ èyí, ọkàn rẹ̀ balẹ̀.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também